ÀKÁ ÌWÉ ORÍ ÍNTÁNẸ́Ẹ̀TÌ ti Watchtower
ÀKÁ ÌWÉ ORÍ ÍŃTÁNẸ́Ẹ̀TÌ
ti Watchtower
Yorùbá
ọ́
  • ẹ
  • ọ
  • ṣ
  • ń
  • ẹ́
  • ẹ̀
  • ọ́
  • ọ̀
  • BÍBÉLÌ
  • ÌTẸ̀JÁDE
  • ÌPÀDÉ
  • w14 12/15 ojú ìwé 32
  • Atọ́ka Àwọn Àkòrí Ilé Ìṣọ́ 2014

Kò sí fídíò kankan ní apá yìí.

Má bínú, fídíò yìí kò jáde.

  • Atọ́ka Àwọn Àkòrí Ilé Ìṣọ́ 2014
  • Ilé Ìṣọ́ Tí Ń Kéde Ìjọba Jehofa—2014
  • Ìsọ̀rí
  • ÀWỌN ẸLẸ́RÌÍ JÈHÓFÀ
  • BÍBÉLÌ
  • BÍBÉLÌ MÁA Ń YÍ ÌGBÉSÍ AYÉ ÀWỌN ÈÈYÀN PA DÀ
  • ÌBÉÈRÈ LÁTI ỌWỌ́ ÀWỌN ÒǸKÀWÉ
  • ÌGBÉSÍ AYÉ ÀTI ÀNÍMỌ́ KRISTẸNI
  • ÌTÀN ÌGBÉSÍ AYÉ
  • JÈHÓFÀ
  • JÉSÙ KRISTI
  • Ọ̀KAN-Ọ̀-JỌ̀KAN
Ilé Ìṣọ́ Tí Ń Kéde Ìjọba Jehofa—2014
w14 12/15 ojú ìwé 32

Atọ́ka Àwọn Àkòrí Ilé Ìṣọ́ 2014

Ó ń tọ́ka sí Ilé Ìṣọ́ tí àpilẹ̀kọ kọ̀ọ̀kan ti jáde

ÀWỌN ÀPILẸ̀KỌ FÚN ÌKẸ́KỌ̀Ọ́

  • A Gbọ́dọ̀ Jẹ́ Mímọ́ Nínú Gbogbo Ìwà Wa, 11/15

  • Àjíǹde Jésù—Àǹfààní Wo Ló Ṣe Wá, 11/15

  • Àwọn Èèyàn Jèhófà “Kọ Àìṣòdodo Sílẹ̀ Ní Àkọ̀tán,” 7/15

  • “Àwọn Ènìyàn Tí Jèhófà Jẹ́ Ọlọ́run Wọn,” 11/15

  • Àwọn Ọ̀nà Tí Jèhófà Gbà Ń Sún Mọ́ Wa, 8/15

  • Bá A Ṣe Lè La Òpin Ayé Ògbólógbòó Yìí Já Pa Pọ̀, 12/15

Bá A Ṣe Lè Máa Sin Jèhófà Kí Àwọn Ọjọ́ Oníwàhálà Tó Dé, 1/15

Bá A Ṣe Lè Máa Tọ́jú Àwọn Àgbàlagbà, 3/15

Báwo Ló Ṣe Yẹ Ká Máa ‘Dá Ẹnì Kọ̀ọ̀kan Lóhùn’? 5/15

Bó O Ṣe Lè Máa Fi Ojú Tó Tọ́ Wo Nǹkan, 3/15

Bó O Ṣe Lè Ṣe Ìpinnu Tó Bọ́gbọ́n Mu Nígbà Ọ̀dọ́, 1/15

‘Ẹ Fetí sí Mi, Kí Ẹ sì Lóye Ìtúmọ̀ Rẹ̀,’ 12/15

Ẹ Máa Bọlá fún Àwọn Àgbàlagbà Tó Wà Láàárín Yín, 3/15

“Ẹ Máa Gbé Èrò Inú Yín Ka Àwọn Nǹkan Ti Òkè,” 10/15

Ẹ Máa Rántí Àwọn Tó Ń Ṣe Iṣẹ́ Ìsìn Alákòókò Kíkún, 9/15

“Ẹ Ó sì Jẹ́ Ẹlẹ́rìí Mi,” 7/15

Ẹ Yin Kristi, Ọba Ògo! 2/15

“Ẹ̀yin Ni Ẹlẹ́rìí Mi,” 7/15

Ẹ̀yin Òbí—Ẹ Máa Kọ́ Àwọn Ọmọ Yín, 9/15

Ẹ̀yin Yóò Di “Ìjọba Àwọn Àlùfáà,” 10/15

Ẹ Yọ̀ Nítorí Ìgbéyàwó Ọ̀dọ́ Àgùntàn! 2/15

Gẹ́gẹ́ Bí Ọ̀tá Ìkẹyìn, Ikú Di Ohun Asán, 9/15

Ìdí Tá A Fi Gbọ́dọ̀ Jẹ́ Mímọ́, 11/15

Ipa Wo Ni Àwọn Obìnrin Ń Kó Nínú Mímú Ìfẹ́ Jèhófà Ṣẹ? 8/15

“Jèhófà Mọ Àwọn Tí Í Ṣe Tirẹ̀,” 7/15

Jèhófà—Olùpèsè àti Aláàbò Wa, 2/15

Jèhófà—Ọ̀rẹ́ Wa Tímọ́tímọ́, 2/15

Jẹ́ Onígboyà—Jèhófà Ni Olùrànlọ́wọ́ Rẹ! 4/15

“Kí Ìjọba Rẹ Dé”—Àmọ́, Nígbà Wo? 1/15

Kò Sí Ẹni Tó Lè Sin Ọ̀gá Méjì, 4/15

Máa Fi Hàn Pé O Ní Ẹ̀mí Ìfara-Ẹni-Rúbọ, 3/15

Máa Fi Ìlànà Pàtàkì Náà Sílò Lóde Ẹ̀rí, 5/15

Máa Gbọ́ Ohùn Jèhófà Níbikíbi Tó O Bá Wà, 8/15

Máa Lo Ọ̀rọ̀ Ọlọ́run—Ọ̀rọ̀ Rẹ̀ Yè! 8/15

Máa Sin Jèhófà Láìyẹsẹ̀ Láìka “Ọ̀pọ̀ Ìpọ́njú” Sí, 9/15

Máa Ṣìkẹ́ Àǹfààní Tó O Ní Láti Jẹ́ Alábàáṣiṣẹ́pọ̀ Pẹ̀lú Jèhófà! 10/15

“Nífẹ̀ẹ́ Aládùúgbò Rẹ Gẹ́gẹ́ Bí Ara Rẹ,” 6/15

“Nífẹ̀ẹ́ Jèhófà Ọlọ́run Rẹ,” 6/15

Ní Ìgbàgbọ́ Tó Fẹsẹ̀ Múlẹ̀ Ṣinṣin Nínú Ìjọba Ọlọ́run, 10/15

“Nísinsìnyí Ẹ Jẹ́ Ènìyàn Ọlọ́run,” 11/15

Ǹjẹ́ Ó Dá Ẹ Lójú Pé O Wà Nínú Òtítọ́? Kí Nìdí? 9/15

Ǹjẹ́ O “Mòye Ìtúmọ̀ Ìwé Mímọ́”? 12/15

Ǹjẹ́ O Mọyì Bí Jèhófà Ṣe Ń Fìfẹ́ Ṣọ́ Wa? 4/15

Ǹjẹ́ O Mọyì Ohun Tí O Ti Rí Gbà? 12/15

Ǹjẹ́ Ò Ń Bá Ètò Jèhófà Rìn Bó Ṣe Ń Tẹ̀ Síwájú? 5/15

Ǹjẹ́ Ò Ń Rí “Ẹni Tí A Kò Lè Rí”? 4/15

Ọgọ́rùn-ún Ọdún Ìṣàkóso Ìjọba Ọlọ́run—Báwo Ló Ṣe Kàn Ọ́? 1/15

Ọlọ́run Ètò Ni Jèhófà, 5/15

Ran Àwọn Mìíràn Lọ́wọ́ Láti Lo Ẹ̀bùn Wọn ní Kíkún, 6/15

Sin Jèhófà, Ọba Ayérayé, 1/15

Ṣé Ojú Tí Jèhófà Fi Ń Wo Àìlera Ẹ̀dá Ni Ìwọ Náà Fi Ń Wò Ó? 6/15

Tẹ̀ Lé Àpẹẹrẹ Ìgbàgbọ́ Mósè, 4/15

ÀWỌN ẸLẸ́RÌÍ JÈHÓFÀ

Àwòkẹ́kọ̀ọ́ Eureka, 8/15

Ẹ̀kọ́ Òtítọ́ Dé Ilẹ̀ Japan, 11/15

‘Ìkórè Ṣì Pọ̀’ (Brazil), 5/15

Ìpinnu Tí Mo Ṣe Nígbà Tí Mo Wà ní Kékeré, 1/15

Ǹjẹ́ A Gba Jésù Gbọ́? 5/1

Ó “Mọ Ọ̀nà” Náà (G.  Pierce), 12/15

Ó Ti Pé Ọgọ́rùn-ún Ọdún Báyìí (Àwòkẹ́kọ̀ọ́ Nípa Ìṣẹ̀dá), 2/15

Wọ́n Yọ̀ǹda Ara Wọn ní Ìwọ̀ Oòrùn Áfíríkà, 1/15

Wọ́n Yọ̀ǹda Ara Wọn ní Micronesia, 7/15

Wọ́n Yọ̀ǹda Ara Wọn ní Taiwan, 10/15

BÍBÉLÌ

Bíbélì Peshitta Lédè Síríákì, 9/1

Bí Wọ́n Ṣe Kọ Ọ́, 2/1

Bó Ṣe Dé Orílẹ̀-èdè Sípéènì, 3/1

Ṣé Òpìtàn Tí Ọ̀rọ̀ Rẹ̀ Péye Ni Lúùkù? 1/1

Ṣé Ọ̀rọ̀ Ọlọ́run Ni Lóòótọ́? 2/1

BÍBÉLÌ MÁA Ń YÍ ÌGBÉSÍ AYÉ ÀWỌN ÈÈYÀN PA DÀ

Bíbélì Ni Wọ́n Fi Dáhùn Gbogbo Ìbéèrè Mi (I. Lamela), 4/1

Ìbọn Máa Ń Wà Lára Mi Níbikíbi Tí Mo Bá Lọ (A. Lugarà), 7/1

Ìlérí Párádísè Yí Ìgbésí Ayé Mi Pa Dà! (I. Vigulis), 2/1

Jèhófà Kò Tíì Gbàgbé Mi (S. Udías), 1/1

Mo Fẹ́ Gba Àwọn Èèyàn Lọ́wọ́ Ìwà Ìrẹ́jẹ àti Ìwà Ipá (A. Touma), 8/1

Tara Mi Nìkan Ni Mo Mọ̀ (C. Bauer), 10/1

ÌBÉÈRÈ LÁTI ỌWỌ́ ÀWỌN ÒǸKÀWÉ

Àwọn wo ni ẹlẹ́rìí méjì? (Ìṣí 11:3-12), 11/15

Báwo la ṣe ń yan àwọn alàgbà àti ìránṣẹ́ iṣẹ́ òjíṣẹ́ sípò? 11/15

“Kì í gbéyàwó, bẹ́ẹ̀ ni a kì í fi wọ́n fúnni nínú ìgbéyàwó” (Lk 20:34-36), 8/15

Kí ló mú kí àwọn Júù ọ̀rúndún kìíní máa “fojú sọ́nà” fún Mèsáyà? (Lk 3:15), 2/15

Kí nìdí tí Rákélì ń sunkún nítorí àwọn ọmọkùnrin rẹ̀? (Jer 31:15), 12/15

Ǹjẹ́ Jèhófà máa jẹ́ kí Kristẹni kan ṣàìní oúnjẹ tí ó tó? (Sm 37:25; Mt 6:33), 9/15

Ṣó yẹ kéèyàn máa fi iná sun òkú? 6/15

ÌGBÉSÍ AYÉ ÀTI ÀNÍMỌ́ KRISTẸNI

Àwọn Ìbátan Wa Tí Kì í Ṣe Ẹlẹ́rìí, 3/15

Borí Ìdẹwò, 4/1

Ẹ̀mí Ìmúratán, 12/15

Gba Oúnjẹ “Ní Àkókò Tí Ó Bẹ́tọ̀ọ́ Mu,” 8/15

Ìjọsìn Ìdílé, 3/15

Kí Nìdí Tó Fi Yẹ Kí O Máa Gbàdúrà? 4/1

‘Mú Ipa Ọ̀nà Jọ̀lọ̀’ Kó O Lè Tẹ̀ Síwájú, 6/15

Ǹjẹ́ “Bẹ́ẹ̀ Ni” Rẹ Kì Í Di “Bẹ́ẹ̀ Kọ́”? 3/15

Ǹjẹ́ Ò Ń ‘Nàgà fún Iṣẹ́ Àtàtà’? 9/15

Ǹjẹ́ Ó Yẹ Kó O Yí Èrò Rẹ Pa Dà? 12/15

‘Oúnjẹ Mi Ni Láti Ṣe Ìfẹ́ Ọlọ́run,’ 5/15

‘Pa Dà Kí O sì Fún Àwọn Arákùnrin Rẹ Lókun,’ 8/15

Ran Àwọn Kristẹni Tí Ọkọ Tàbí Ìyàwó Wọn Kọ̀ Sílẹ̀ Lọ́wọ́, 6/15

ÌTÀN ÌGBÉSÍ AYÉ

Àwọn Ìṣẹ̀lẹ̀ Pàtàkì Nígbèésí Ayé Mi Lẹ́nu Iṣẹ́ Ìjọba Ọlọ́run (M. Olson), 10/15

Baba Kú Àmọ́, Baba Kù (G. Lösch), 7/15

Bí Mo Tiẹ̀ Jẹ́ Aláìlera, Okun Inú Ń Gbé Mi Ró (M. Morlans), 3/1

Ibi Tí Iṣẹ́ Òjíṣẹ́ Alákòókò Kíkún Gbé Mi Dé (R. Wallen), 4/15

Ìgbésí Ayé Mi Lẹ́nu Iṣẹ́ Ìsìn Ọlọ́run Mérè Wá (P. Carrbello), 9/1

Jèhófà Ti Ràn Mí Lọ́wọ́ (K. Little), 5/15

JÈHÓFÀ

“Adùn Jèhófà” (Sm 27:4), 2/15

Báwo La Ṣe Lè Rí Ọlọ́run? 7/1

Bó O Ṣe Lè Kọ́ Àwọn Ọmọ Rẹ Láti Nífẹ̀ẹ́ Ọlọ́run, 12/1

Ẹni, 1/1

Ìdí Tí Ọlọ́run Fi Fàyè Gba Ìnilára, 2/1

Ìdí Tí Ọlọ́run Fi Fàyè Gba Ìyà Tó Ń Jẹ Aráyé, 1/1

Ǹjẹ́ Ọlọ́run Bìkítà Nípa Rẹ? 8/1

Ohun Tí Ọlọ́run Ti Ṣe fún Ẹ, 3/1

Ojú Tó Fi Ń Wo Ìwà Ìrẹ́jẹ, 1/1

O Lè Sún Mọ́ Ọlọ́run, 12/1

Ó Ń Bù Kún Àwọn Tó Ní Ẹ̀mí Ìmúratán, 12/15

Ta Ló Dá Ọlọ́run? 8/1

JÉSÙ KRISTI

Àǹfààní Tí Ikú Jésù Ṣe fún Wa, 3/1

Báwo Ló Ṣe Yẹ Ká Máa Rántí Ikú Jésù? 3/1

Ìṣẹ̀lẹ̀ Pàtàkì Kan Tó Yẹ Kó Ṣojú Ẹ (Ìrántí Ikú Kristi), 3/1

Kí Ló Máa Ṣe Lọ́jọ́ Iwájú? 4/1

Kí Ló Ń Ṣe Nísinsìnyí? 4/1

Ó Jí Àwọn Èèyàn Dìde, Kí Nìdí? 11/1

Ọ̀KAN-Ọ̀-JỌ̀KAN

Álóè, 2/1

Àmúlùmálà Ìgbàgbọ́, 3/1

Aró Aláwọ̀ Àlùkò, 4/1

Àwọn Áńgẹ́lì, 9/1

Àwọn Ẹrú Ní Ìlú Róòmù, 4/1

Àwọn Mẹ́ta Tó Wá Òtítọ́ Ní Ọgọ́rùn-ún Ọdún Kẹrìndínlógún, 6/1

Bí Àwọn Atukọ̀ Òkun Ṣe Ń Ṣe Ọkọ̀ Òkun Wọn Kí Omi Má Bàa Wọnú Rẹ̀, 7/1

Bí O Ṣe Lè Bá Àwọn Ọmọ Rẹ Wí, 7/1

Bí Wọ́n Ṣe Máa Ń Fi Kànnàkànnà Jagun Láyé Àtijọ́, 5/1

Bí Wọ́n Ṣe Ń Fi Ọrẹ Ṣètìlẹyìn Nínú Tẹ́ńpìlì, 1/1

Bí Wọ́n Ṣe Ń Tọ́jú Ẹja Láyé Àtijọ́ Kó Má Bàa Bàjẹ́, 7/1

Búrẹ́dì Tí Ń Fúnni Ní Ìyè, 6/1

‘Èmi Kò Lè Hùwà Búburú Ńlá Yìí’ (Jósẹ́fù), 11/1

“Ẹ Jọ̀wọ́, Ẹ Fetí sí Àlá Tí Mo Lá” (Jósẹ́fù), 8/1

Fífarada Ìwà Ìrẹ́jẹ (Èlíjà), 2/1

Ìdí Tí Ọlọ́run Fi Dá Ilẹ̀ Ayé, 6/1

Ìgbà Tí Ìjọba Ọlọ́run Bẹ̀rẹ̀, 10/1, 11/1

‘Ìjìnlẹ̀ Òye Máa Ń Dẹwọ́ Ìbínú,’ 12/1

Ìjọba Ọlọ́run—Àǹfààní Tó Máa Ṣe Ẹ́, 10/1

Ìrètí Tó Wà Fún Àwọn Òkú, 1/1

Ìrètí Wo Ló Wà Fún Àwọn Baba Ńlá Tó Ti Kú? 6/1

Ìsìn Tòótọ́, 8/1

Kérésìmesì, 12/1

Kí Ló Túmọ̀ Sí Láti Gbọn Ẹ̀wù Ya? 4/15

Kí Nìdí Tí Nǹkan Burúkú Fi Ń Ṣẹlẹ̀ Sáwọn Èèyàn Rere? 7/1

Kí Nìdí Tí Wọ́n Fi Máa Ń Ṣẹ́ Ẹsẹ̀ Àwọn Tí Wọ́n Fẹ́ Pa? 5/1

Kí Nìdí Tó Fi Yẹ Ká Gbàdúrà? Báwo La Ṣe Lè Gbà Á? 7/1

Kí Nìdí Tó Fi Yẹ Ká Máa Gbàdúrà Pé Kí Ìjọba Ọlọ́run Dé? 10/1

Ǹjẹ́ Òfin Tí Ọlọ́run Fún Àwọn Ọmọ Ísírẹ́lì Bá Ẹ̀tọ́ Mu? 9/1

Ǹjẹ́ Ó Yẹ Kí N Yáwó? 12/1

Ó Fara Da Ọgbẹ́ Ọkàn (Màríà), 5/1

Ogun Tó Da Ayé Rú (Ogun Àgbáyé Kìíní), 2/1

Ojú Tí Ọlọ́run Fi Ń Wo Sìgá Mímu, 6/1

Opó Sáréfátì, 2/15

Ọrẹ Ẹbọ Tẹ́ńpìlì, 2/1

Ṣé Àwọn Èèyàn Ò Ní Ba Ayé Yìí Jẹ́ Kọjá Àtúnṣe? 9/1

Ṣé Ikú Ni Òpin Ìgbésí Ayé Ẹ̀dá? 1/1

Ṣé Sátánì Wà Lóòótọ́? 11/1

Ta Ló Mọ Ọjọ́ Ọ̀la? 5/1

Ta Ló Ń Darí Ayé Yìí? 5/1

Thomas Emlyn (ọ̀mọ̀wé), 4/1

Timgad—Ìlú Àtijọ́, 12/1

    Yorùbá Publications (1987-2025)
    Jáde
    Wọlé
    • Yorùbá
    • Fi Ráńṣẹ́
    • Èyí tí mo fẹ́ràn jù
    • Copyright © 2025 Watch Tower Bible and Tract Society of Pennsylvania
    • Àdéhùn Nípa Lílò
    • Òfin
    • Ètò Nípa Ìsọfúnni Rẹ
    • JW.ORG
    • Wọlé
    Fi Ráńṣẹ́