ÀKÁ ÌWÉ ORÍ ÍNTÁNẸ́Ẹ̀TÌ ti Watchtower
ÀKÁ ÌWÉ ORÍ ÍŃTÁNẸ́Ẹ̀TÌ
ti Watchtower
Yorùbá
ọ́
  • ẹ
  • ọ
  • ṣ
  • ń
  • ẹ́
  • ẹ̀
  • ọ́
  • ọ̀
  • BÍBÉLÌ
  • ÌTẸ̀JÁDE
  • ÌPÀDÉ
  • mwb17 March ojú ìwé 3
  • Wọn Ò Ṣe Ohun Tí Jèhófà Fẹ́ Mọ́

Kò sí fídíò kankan ní apá yìí.

Má bínú, fídíò yìí kò jáde.

  • Wọn Ò Ṣe Ohun Tí Jèhófà Fẹ́ Mọ́
  • Ìgbésí Ayé àti Iṣẹ́ Òjíṣẹ́ Àwa Kristẹni​—Ìwé Ìpàdé (2017)
  • Àpilẹ̀kọ Míì Tó Jọ ọ́
  • Jẹ́ Onígboyà Bíi Jeremáyà
    Ìgbésí Ayé àti Iṣẹ́ Òjíṣẹ́ Àwa Kristẹni​—Ìwé Ìpàdé (2017)
  • “Mo Ti Fi Ọ̀rọ̀ Mi sí Ẹnu Rẹ”
    Ọ̀rọ̀ Tí Ọlọ́run Bá Wa Sọ Nípasẹ̀ Jeremáyà
  • Jeremáyà Ń Bá A Lọ Láti Sọ̀rọ̀ Nípa Jèhófà
    Kọ́ Ọmọ Rẹ
  • Ǹjẹ́ O Máa Ń Béèrè Lójoojúmọ́ Pé, “Jèhófà Dà?”
    Ọ̀rọ̀ Tí Ọlọ́run Bá Wa Sọ Nípasẹ̀ Jeremáyà
Àwọn Míì
Ìgbésí Ayé àti Iṣẹ́ Òjíṣẹ́ Àwa Kristẹni​—Ìwé Ìpàdé (2017)
mwb17 March ojú ìwé 3

ÀWỌN ÌṢÚRA INÚ Ọ̀RỌ̀ ỌLỌ́RUN | JEREMÁYÀ 5-7

Wọn Ò Ṣe Ohun Tí Ọlọ́run Fẹ́ Mọ́

7:​1-4, 8-10, 15

  • Jeremáyà fi ìgboyà tú àṣírí ẹ̀ṣẹ̀ àwọn ọmọ Ísírẹ́lì àti ìwà àgàbàgebè wọn

  • Àwọn ọmọ Ísírẹ́lì ka tẹ́ńpìlì sí oògùn ajẹ́bíidán tó máa dáàbò bò wọ́n

  • Jèhófà jẹ́ kí wọ́n mọ̀ pé àwọn ẹbọ tí wọ́n ń rú kò lè bo ìwà àìtọ́ wọn mọ́lẹ̀

Bi ara rẹ pé: Báwo ló ṣe lè dá mi lójú pé ìjọsìn mi bá ìfẹ́ inú Jèhófà mu àti pé kì í ṣe ìjọsìn ojú lásán?

Jeremáyà ń kéde ọ̀rọ̀ Jèhófà lẹ́nu ọ̀nà tẹ́ńpìlì

Jeremáyà dúró lẹ́nu ọ̀nà ilé Jèhófà

    Yorùbá Publications (1987-2025)
    Jáde
    Wọlé
    • Yorùbá
    • Fi Ráńṣẹ́
    • Èyí tí mo fẹ́ràn jù
    • Copyright © 2025 Watch Tower Bible and Tract Society of Pennsylvania
    • Àdéhùn Nípa Lílò
    • Òfin
    • Ètò Nípa Ìsọfúnni Rẹ
    • JW.ORG
    • Wọlé
    Fi Ráńṣẹ́