ÀKÁ ÌWÉ ORÍ ÍNTÁNẸ́Ẹ̀TÌ ti Watchtower
ÀKÁ ÌWÉ ORÍ ÍŃTÁNẸ́Ẹ̀TÌ
ti Watchtower
Yorùbá
ọ́
  • ẹ
  • ọ
  • ṣ
  • ń
  • ẹ́
  • ẹ̀
  • ọ́
  • ọ̀
  • BÍBÉLÌ
  • ÌTẸ̀JÁDE
  • ÌPÀDÉ
  • mwb17 April ojú ìwé 7
  • Jẹ́ Onígboyà Bíi Jeremáyà

Kò sí fídíò kankan ní apá yìí.

Má bínú, fídíò yìí kò jáde.

  • Jẹ́ Onígboyà Bíi Jeremáyà
  • Ìgbésí Ayé àti Iṣẹ́ Òjíṣẹ́ Àwa Kristẹni​—Ìwé Ìpàdé (2017)
  • Àpilẹ̀kọ Míì Tó Jọ ọ́
  • “Mo Ti Fi Ọ̀rọ̀ Mi sí Ẹnu Rẹ”
    Ọ̀rọ̀ Tí Ọlọ́run Bá Wa Sọ Nípasẹ̀ Jeremáyà
  • Jèhófà Rán Jeremáyà Pé Kó Lọ Wàásù
    Àwọn Ẹ̀kọ́ Tó O Lè Kọ́ Látinú Bíbélì
  • Àwọn Wo Ló Yẹ Kó O Yàn Lọ́rẹ̀ẹ́?
    Ọ̀rọ̀ Tí Ọlọ́run Bá Wa Sọ Nípasẹ̀ Jeremáyà
  • “Èmi Kò Lè Dákẹ́”
    Ọ̀rọ̀ Tí Ọlọ́run Bá Wa Sọ Nípasẹ̀ Jeremáyà
Àwọn Míì
Ìgbésí Ayé àti Iṣẹ́ Òjíṣẹ́ Àwa Kristẹni​—Ìwé Ìpàdé (2017)
mwb17 April ojú ìwé 7

ÀWỌN ÌṢÚRA INÚ Ọ̀RỌ̀ ỌLỌ́RUN | JEREMÁYÀ 25-28

Jẹ́ Onígboyà Bíi Jeremáyà

Jeremáyà kìlọ̀ pé Jerúsálẹ́mù máa dahoro

Jeremáyà kìlọ̀ pé Jerúsálẹ́mù máa dahoro bí ìlú Ṣílò

26:6

  • Ìgbà kan wà tí wọ́n tọ́jú àpótí ẹ̀rí tó ṣàpẹẹrẹ pé Jèhófà wà láàárín àwọn èèyàn rẹ̀ sí ìlú Ṣílò

  • Jèhófà gbà kí àwọn Filísínì gbé Àpótí náà, bó ṣe di pé kò pa dà sí Ṣílò mọ́ nìyẹn

Àwọn àlùfáà, wòlí ì àtàwọn èèyan náà gbá Jeremáyà mu

Àwọn àlùfáà, wòlíì àtàwọn èèyan náà lérí pé àwọn máa pa Jeremáyà

26:8, 9, 12, 13

  • Àwọn èèyàn náà gbá Jeremáyà mú torí pé ó sọ àsọtẹ́lẹ̀ pé Jerúsálẹ́mù àti tẹ́ńpìlì rẹ̀ máa pa run

  • Jeremáyà kò pa iṣẹ́ tí Jèhófà gbé lé e lọ́wọ́ tì, kó wá sá lọ

Wòlí ì Jeremáyà

Jèhófà dáàbò bo Jeremáyà

26:​16, 24

  • Jeremáyà jẹ́ onígboyà, Jèhófà kò sì fi í sílẹ̀

  • Jèhófà lo ọkùnrin onígboyà náà, Áhíkámù láti dáàbò bo Jeremáyà

Torí pé Jèhófà ti Jeremáyà lẹ́yìn tó sì fún un níṣìírí, ogójì [40] ọdún gbáko ló fi wàásù ohun táwọn èèyàn ò nífẹ̀ẹ́ sí

    Yorùbá Publications (1987-2025)
    Jáde
    Wọlé
    • Yorùbá
    • Fi Ráńṣẹ́
    • Èyí tí mo fẹ́ràn jù
    • Copyright © 2025 Watch Tower Bible and Tract Society of Pennsylvania
    • Àdéhùn Nípa Lílò
    • Òfin
    • Ètò Nípa Ìsọfúnni Rẹ
    • JW.ORG
    • Wọlé
    Fi Ráńṣẹ́