ÀKÁ ÌWÉ ORÍ ÍNTÁNẸ́Ẹ̀TÌ ti Watchtower
ÀKÁ ÌWÉ ORÍ ÍŃTÁNẸ́Ẹ̀TÌ
ti Watchtower
Yorùbá
ọ́
  • ẹ
  • ọ
  • ṣ
  • ń
  • ẹ́
  • ẹ̀
  • ọ́
  • ọ̀
  • BÍBÉLÌ
  • ÌTẸ̀JÁDE
  • ÌPÀDÉ
  • mwb18 July ojú ìwé 5
  • “Ẹ Níye Lórí Ju Ọ̀pọ̀ Ológoṣẹ́”

Kò sí fídíò kankan ní apá yìí.

Má bínú, fídíò yìí kò jáde.

  • “Ẹ Níye Lórí Ju Ọ̀pọ̀ Ológoṣẹ́”
  • Ìgbésí Ayé àti Iṣẹ́ Òjíṣẹ́ Kristẹni—Ìwé Ìpàdé—2018
  • Àpilẹ̀kọ Míì Tó Jọ ọ́
  • Ẹni Tó Mọyì Wa Gan-an
    Ilé Ìṣọ́ Tí Ń Kéde Ìjọba Jehofa—2008
  • Jèhófà Mọ Iye ‘Irun Orí Rẹ’
    Ilé Ìṣọ́ Tí Ń Kéde Ìjọba Jehofa—2005
  • O Ṣeyebíye Lójú Ọlọ́run!
    Jí!—1999
  • Máa Rántí Gbàdúrà Fáwọn Kristẹni Tí Wọ́n Ń Ṣe Inúnibíni Sí
    Ìgbésí Ayé àti Iṣẹ́ Òjíṣẹ́ Àwa Kristẹni​—Ìwé Ìpàdé (2017)
Àwọn Míì
Ìgbésí Ayé àti Iṣẹ́ Òjíṣẹ́ Kristẹni—Ìwé Ìpàdé—2018
mwb18 July ojú ìwé 5

ÀWỌN ÌṢÚRA INÚ Ọ̀RỌ̀ ỌLỌ́RUN | LÚÙKÙ 12-13

“Ẹ Níye Lórí Ju Ọ̀pọ̀ Ológoṣẹ́”

12:6, 7

Ẹyẹ ológoṣẹ́ méjì

Kí ni Jésù sọ kó tó wá sọ ọ̀rọ̀ tó wà nínú Lúùkù 12:​6, 7? Ní ẹsẹ 4, a kà níbẹ̀ pé Jésù sọ fún àwọn ọmọlẹ́yìn rẹ̀ pé kí wọ́n má bẹ̀rù àwọn tó ṣeé ṣe kó ta kò wọ́n tàbí àwọn tó tiẹ̀ ṣeé ṣe kó pa wọ́n. Ńṣe ni Jésù ń múra àwọn ọmọlẹ́yìn rẹ̀ sílẹ̀ fún àtakò tí wọ́n máa dojú kọ. Ó sì mú kó dá wọn lójú pé Jèhófà mọyì ọ̀kọ̀ọ̀kan àwọn ìránṣẹ́ Rẹ̀ àti pé kò ní jẹ́ kí jàǹbá ayérayé ṣẹlẹ̀ sí wọn.

Báwo la ṣe lè fi hàn pé ọ̀rọ̀ àwọn ará wa tí wọ́n ń ṣe inúnibíni sí ń jẹ wá lọ́kàn bíi ti Jèhófà?

Ibo la ti lè rí ìsọfúnni tó dé kẹ́yìn nípa àwọn Ẹlẹ́rìí Jèhófà tí wọ́n jù sẹ́wọ̀n nítorí ìgbàgbọ́ wọn?

Lọ́wọ́lọ́wọ́ báyìí, àwọn arákùnrin àti arábìnrin mélòó ló wà lẹ́wọ̀n?

Arákùnrin kan ń gbàdúrà nínú ẹ̀wọ̀n
    Yorùbá Publications (1987-2025)
    Jáde
    Wọlé
    • Yorùbá
    • Fi Ráńṣẹ́
    • Èyí tí mo fẹ́ràn jù
    • Copyright © 2025 Watch Tower Bible and Tract Society of Pennsylvania
    • Àdéhùn Nípa Lílò
    • Òfin
    • Ètò Nípa Ìsọfúnni Rẹ
    • JW.ORG
    • Wọlé
    Fi Ráńṣẹ́