ÀKÁ ÌWÉ ORÍ ÍNTÁNẸ́Ẹ̀TÌ ti Watchtower
ÀKÁ ÌWÉ ORÍ ÍŃTÁNẸ́Ẹ̀TÌ
ti Watchtower
Yorùbá
ọ́
  • ẹ
  • ọ
  • ṣ
  • ń
  • ẹ́
  • ẹ̀
  • ọ́
  • ọ̀
  • BÍBÉLÌ
  • ÌTẸ̀JÁDE
  • ÌPÀDÉ
  • mwb19 June ojú ìwé 6
  • “Ẹ Má Ṣe Máa Ṣàníyàn Nípa Ohunkóhun”

Kò sí fídíò kankan ní apá yìí.

Má bínú, fídíò yìí kò jáde.

  • “Ẹ Má Ṣe Máa Ṣàníyàn Nípa Ohunkóhun”
  • Ìgbésí Ayé àti Iṣẹ́ Òjíṣẹ́ Kristẹni—Ìwé Ìpàdé—2019
  • Àpilẹ̀kọ Míì Tó Jọ ọ́
  • Báwo Ni Mo Ṣe Lè Borí Àníyàn?
    Àwọn Ọ̀dọ́ Béèrè Pé
  • Kó Gbogbo Àníyàn Rẹ lé Jèhófà
    Ilé Ìṣọ́ Tí Ń Kéde Ìjọba Jehofa (Ẹ̀dà Tó Wà fún Ìkẹ́kọ̀ọ́)—2016
  • ‘Àlàáfíà Ọlọ́run Ta Gbogbo Ìrònú Yọ’
    Ilé Ìṣọ́ Tí Ń Kéde Ìjọba Jehofa (Ẹ̀dà Tó Wà fún Ìkẹ́kọ̀ọ́)—2017
  • Ẹ Kó Gbogbo Àníyàn Yín Lé Jehofa
    Ilé-Ìṣọ́nà Tí Ń Kéde Ìjọba Jehofa—1994
Àwọn Míì
Ìgbésí Ayé àti Iṣẹ́ Òjíṣẹ́ Kristẹni—Ìwé Ìpàdé—2019
mwb19 June ojú ìwé 6

ÀWỌN ÌṢÚRA INÚ Ọ̀RỌ̀ ỌLỌ́RUN | FÍLÍPÌ 1-4

“Ẹ Má Ṣe Máa Ṣàníyàn Nípa Ohunkóhun”

4:​6, 7

Ara tu arábìnrin kan lẹ́yìn tó gbàdúrà tán
  • Àdúrà ni oògùn àníyàn

  • Tá a bá gbàdúrà, tá a sì ní ìgbàgbọ́, Jèhófà máa fún wa ní àlàáfíà “tó kọjá gbogbo òye”

  • Lóòótọ́ ó lè jọ pé kò sí ọ̀nà àbáyọ sí àwọn ìṣòro wa, àmọ́ Jèhófà lè ràn wá lọ́wọ́ láti fara dà á. Ó tiẹ̀ lè ṣe kọjá ohun tá a rò pàápàá.​—1Kọ 10:13

Kí làwọn nǹkan tó ń gbé mi lọ́kàn sókè?

Báwo ni mo ṣe lè túbọ̀ fi hàn pé Jèhófà ni mo gbẹ́kẹ̀ lé?

Arábìnrin kan ń ṣàníyàn nítorí gbèsè; arábìnrin àgbàlagbà kan ń gbàdúrà lẹ́gbẹ̀ẹ́ ọkọ rẹ̀ tó ń ṣàìsàn; àwọn òbí kan ń bá ara wọn jiyàn, àwọn ọmọ wọn ń wò wọ́n, wọ́n sì ń gbọ́ ohun tí wọ́n ń sọ
    Yorùbá Publications (1987-2025)
    Jáde
    Wọlé
    • Yorùbá
    • Fi Ráńṣẹ́
    • Èyí tí mo fẹ́ràn jù
    • Copyright © 2025 Watch Tower Bible and Tract Society of Pennsylvania
    • Àdéhùn Nípa Lílò
    • Òfin
    • Ètò Nípa Ìsọfúnni Rẹ
    • JW.ORG
    • Wọlé
    Fi Ráńṣẹ́