JÉMÍÌSÌ
OHUN TÓ WÀ NÍNÚ ÌWÉ YÌÍ
1
Ìkíni (1)
Ìfaradà ń jẹ́ ká láyọ̀ (2-15)
A máa ń dán ìgbàgbọ́ wò ní ti bó ṣe jẹ́ ojúlówó tó (3)
Ẹ máa fi ìgbàgbọ́ béèrè (5-8)
Ìfẹ́ ọkàn máa ń yọrí sí ẹ̀ṣẹ̀ àti ikú (14, 15)
Gbogbo ẹ̀bùn rere wá láti òkè (16-18)
Olùgbọ́ àti olùṣe ọ̀rọ̀ náà (19-25)
Ìjọsìn tó mọ́, tí kò sì ní ẹ̀gbin (26, 27)
2
3
4
5
Ìkìlọ̀ fún àwọn ọlọ́rọ̀ (1-6)
Ọlọ́run ń bù kún àwọn tó ní sùúrù àti ìfaradà (7-11)
Ẹ jẹ́ kí “bẹ́ẹ̀ ni” yín jẹ́ bẹ́ẹ̀ ni (12)
Àdúrà ìgbàgbọ́ lágbára (13-18)
Ran ẹlẹ́ṣẹ̀ lọ́wọ́ kó lè yí pa dà (19, 20)