ÀKÁ ÌWÉ ORÍ ÍNTÁNẸ́Ẹ̀TÌ ti Watchtower
ÀKÁ ÌWÉ ORÍ ÍŃTÁNẸ́Ẹ̀TÌ
ti Watchtower
Yorùbá
ọ́
  • ẹ
  • ọ
  • ṣ
  • ń
  • ẹ́
  • ẹ̀
  • ọ́
  • ọ̀
  • BÍBÉLÌ
  • ÌTẸ̀JÁDE
  • ÌPÀDÉ
  • CO-pgm18 ojú ìwé 4-5
  • Saturday

Kò sí fídíò kankan ní apá yìí.

Má bínú, fídíò yìí kò jáde.

  • Saturday
  • Ìtòlẹ́sẹẹsẹ Àpéjọ Àgbègbè ti Ọdún 2018
  • Àpilẹ̀kọ Míì Tó Jọ ọ́
  • Saturday
    Ìtòlẹ́sẹẹsẹ Àpéjọ Àgbègbè ti Ọdún 2020
  • Saturday
    Ìtòlẹ́sẹẹsẹ Àpéjọ Àgbègbè ti Ọdún 2021
  • Saturday
    Ìtòlẹ́sẹẹsẹ Àpéjọ Àgbègbè ti Ọdún 2019
  • Saturday
    Ìtòlẹ́sẹẹsẹ Àpéjọ Àgbègbè ti Ọdún 2017
Àwọn Míì
Ìtòlẹ́sẹẹsẹ Àpéjọ Àgbègbè ti Ọdún 2018
CO-pgm18 ojú ìwé 4-5
Gídíónì àtàwọn ọkùnrin rẹ̀ fun ìwo, wọ́n fọ́ ìṣà mọ́lẹ̀, wọ́n mú iná lọ́wọ́, wọ́n sì pariwo

Saturday

‘Wọ́n ń fi ìgboyà púpọ̀ sí i hàn láti sọ ọ̀rọ̀ Ọlọ́run láìbẹ̀rù’​—FÍLÍPÌ 1:14

ÒWÚRỌ̀

  • 9:20 Fídíò Orin

  • 9:30 Orin 76 àti Àdúrà

  • 9:40 ÀPÍNSỌ ÀSỌYÉ: Ẹ Jẹ́ Onígboyà . . .

    • Ẹ̀yin Akẹ́kọ̀ọ́ Bíbélì (Ìṣe 8:35, 36; 13:48)

    • Ẹ̀yin Ọ̀dọ́ (Sáàmù 71:5; Òwe 2:11)

    • Ẹ̀yin Akéde (1 Tẹsalóníkà 2:2)

    • Ẹ̀yin Tọkọtaya (Éfésù 4:26, 27)

    • Ẹ̀yin Òbí (1 Sámúẹ́lì 17:55)

    • Ẹ̀yin Aṣáájú-Ọ̀nà (1 Àwọn Ọba 17:6-8, 12, 16)

    • Ẹ̀yin Alàgbà Ìjọ (Ìṣe 20:28-30)

    • Ẹ̀yin Àgbàlagbà (Dáníẹ́lì 6:10, 11; 12:13)

  • 10:50 Orin 119 àti Ìfilọ̀

  • 11:00 ÀPÍNSỌ ÀSỌYÉ: Tẹ̀ Lé Àpẹẹrẹ Àwọn Tó Nígboyà, Kì Í Ṣe Àwọn Ojo!

    • Má Tẹ̀ Lé Àwọn Ìjòyè Mẹ́wàá, Tẹ̀ Lé Jóṣúà àti Kálébù (Númérì 14:7-9)

    • Má Tẹ̀ Lé Àwọn Aráàlú Mérósì, Tẹ̀ Lé Jáẹ́lì (Àwọn Onídàájọ́ 5:23)

    • Má Tẹ̀ Lé Àwọn Wòlíì Èké, Tẹ̀ Lé Mikáyà (1 Àwọn Ọba 22:14)

    • Má Tẹ̀ Lé Úríjà, Tẹ̀ Lé Jeremáyà (Jeremáyà 26:21-23)

    • Má Tẹ̀ Lé Ọ̀dọ́kùnrin Ọlọ́rọ̀ Tó Jẹ́ Alákòóso, Tẹ̀ Lé Pọ́ọ̀lù (Máàkù 10:21, 22)

  • 11:45 ÌRÌBỌMI: “Àwa Kì Í Ṣe Irú Àwọn Tí Ń Fà Sẹ́yìn”! (Hébérù 10:35, 36, 39; 11:30, 32-34, 36; 1 Pétérù 5:10)

  • 12:15 Orin 38 àti Àkókò Ìsinmi

Nehemáyà darí ṣíṣe àtúnkọ́ ògiri Jerúsálẹ́mù àti fífi àwọn ẹ̀ṣọ́ sí ẹnubodè; Jésù ń gbàdúrà

Ọ̀SÁN

  • 1:35 Fídíò Orin

  • 1:45 Orin 111

  • 1:50 ÀPÍNSỌ ÀSỌYÉ: Kọ́ Ìgboyà Lára Àwọn Ohun Tí Ọlọ́run Dá

    • Kìnnìún (Míkà 5:8)

    • Ẹṣin (Jóòbù 39:19-25)

    • Asín Igbó (Sáàmù 91:3, 13-15)

    • Ẹyẹ Akùnyùnmù (1 Pétérù 3:15)

    • Erin (Òwe 17:17)

  • 2:40 Orin 60 àti Ìfilọ̀

  • 2:50 ÀPÍNSỌ ÀSỌYÉ: Bí Àwọn Ará Wa Ṣe Ń Fi Hàn Pé Àwọn Nígboyà ní . . .

    • Áfíríkà (Mátíù 10:36-39)

    • Éṣíà (Sekaráyà 2:8)

    • Yúróòpù (Ìṣípayá 2:10)

    • Amẹ́ríkà Ti Àríwá (Aísáyà 6:8)

    • Oceania (Sáàmù 94:14, 19)

    • Amẹ́ríkà Ti Gúúsù (Sáàmù 34:19)

  • 4:15 Jẹ́ Onígboyà àmọ́ Má Ṣe Dá Ara Rẹ Lójú Jù! (Òwe 3:​5, 6; Aísáyà 25:9; Jeremáyà 17:5-10; Jòhánù 5:19)

  • 4:50 Orin 3 àti Àdúrà Ìparí

    Yorùbá Publications (1987-2025)
    Jáde
    Wọlé
    • Yorùbá
    • Fi Ráńṣẹ́
    • Èyí tí mo fẹ́ràn jù
    • Copyright © 2025 Watch Tower Bible and Tract Society of Pennsylvania
    • Àdéhùn Nípa Lílò
    • Òfin
    • Ètò Nípa Ìsọfúnni Rẹ
    • JW.ORG
    • Wọlé
    Fi Ráńṣẹ́