ÀKÁ ÌWÉ ORÍ ÍNTÁNẸ́Ẹ̀TÌ ti Watchtower
ÀKÁ ÌWÉ ORÍ ÍŃTÁNẸ́Ẹ̀TÌ
ti Watchtower
Yorùbá
ọ́
  • ẹ
  • ọ
  • ṣ
  • ń
  • ẹ́
  • ẹ̀
  • ọ́
  • ọ̀
  • BÍBÉLÌ
  • ÌTẸ̀JÁDE
  • ÌPÀDÉ
  • CO-pgm21 ojú ìwé 2-3
  • Friday

Kò sí fídíò kankan ní apá yìí.

Má bínú, fídíò yìí kò jáde.

  • Friday
  • Ìtòlẹ́sẹẹsẹ Àpéjọ Àgbègbè ti Ọdún 2021
  • Àpilẹ̀kọ Míì Tó Jọ ọ́
  • Sunday
    Ìtòlẹ́sẹẹsẹ Àpéjọ Àgbègbè ti Ọdún 2021
  • Saturday
    Ìtòlẹ́sẹẹsẹ Àpéjọ Àgbègbè ti Ọdún 2021
  • Friday
    Ìtòlẹ́sẹẹsẹ Àpéjọ Agbègbè ti Ọdún 2022
  • Friday
    Ìtòlẹ́sẹẹsẹ Àpéjọ Àgbègbè ti Ọdún 2019
Àwọn Míì
Ìtòlẹ́sẹẹsẹ Àpéjọ Àgbègbè ti Ọdún 2021
CO-pgm21 ojú ìwé 2-3
Àwòrán: 1. Nóà mú àáké dání, ó ń wo àwọn igi tó ga nínú igbó. 2. Bí ayé, oòrùn àtàwọn ìràwọ̀ ṣe rí tá a bá wò ó láti gbalasa òfúrufú. 3. Ẹja àbùùbùtán kan àti ọmọ rẹ̀ nínú omi.

Friday

“Fún wa ní ìgbàgbọ́ sí i”​—Lúùkù 17:5

ÀÁRỌ̀

  • 9:20 Fídíò Orin

  • 9:30 Orin 5 àti Àdúrà

  • 9:40 Ọ̀RỌ̀ ALÁGA: Báwo Ni Ìgbàgbọ́ Ṣe Lágbára Tó? (Mátíù 17:​19, 20; Hébérù 11:1)

  • 10:10 ÀPÍNSỌ ÀSỌYÉ: Ìdí Tá A Fi Gbà Gbọ́ Pé . . .

    • • Ọlọ́run Wà (Éfésù 2:1, 12; Hébérù 11:3)

    • • Ọ̀rọ̀ Ọlọ́run Ni Bíbélì (Àìsáyà 46:10)

    • • Ìlànà Ọlọ́run Ló Dáa Jù (Àìsáyà 48:17)

    • • Ọlọ́run Nífẹ̀ẹ́ Wa (Jòhánù 6:44)

  • 11:05 Orin 37 àti Ìfilọ̀

  • 11:15 BÍBÉLÌ KÍKÀ BÍ ẸNI ṢE ERÉ ÌTÀN: Ìgbàgbọ́ Mú Kí Nóà Ṣègbọràn (Jẹ́nẹ́sísì 6:1–8:22; 9:8-16)

  • 11:45 ‘Ẹ Ní Ìgbàgbọ́, Ẹ Má sì Ṣiyèméjì’ (Mátíù 21:21, 22)

  • 12:15 Orin 118 àti Àkókò Ìsinmi

Ọ̀SÁN

  • 1:35 Fídíò Orin

  • 1:45 Orin 2

  • 1:50 ÀPÍNSỌ ÀSỌYÉ: Jẹ́ Kí Àwọn Ohun Tí Jèhófà Dá Mú Kí Ìgbàgbọ́ Rẹ Lágbára Sí I

    • • Àwọn Ìràwọ̀ (Àìsáyà 40:26)

    • • Òkun (Sáàmù 93:4)

    • • Igbó Kìjikìji (Sáàmù 37:10, 11, 29)

    • • Ẹ̀fúùfù àti Omi (Sáàmù 147:17, 18)

    • • Àwọn Ẹ̀dá Inú Òkun (Sáàmù 104:27, 28)

    • • Ara Àwa Èèyàn (Àìsáyà 33:24)

  • 2:50 Orin 148 àti Ìfilọ̀

  • 3:00 Àwọn Iṣẹ́ Agbára Jèhófà Ń Mú Kí Ìgbàgbọ́ Wa Lágbára (Àìsáyà 43:10; Hébérù 11:32-35)

  • 3:20 ÀPÍNSỌ ÀSỌYÉ: Tẹ̀ Lé Àpẹẹrẹ Àwọn Tó Nígbàgbọ́, Kì Í Ṣe Àwọn Tí Kò Nígbàgbọ́

    • • Tẹ̀ Lé Ébẹ́lì, Má Tẹ̀ Lé Kéènì (Hébérù 11:4)

    • • Tẹ̀ Lé Énọ́kù, Má Tẹ̀ Lé Lámékì (Hébérù 11:5)

    • • Tẹ̀ Lé Nóà, Má Tẹ̀ Lé Àwọn Aládùúgbò Rẹ̀ (Hébérù 11:7)

    • • Tẹ̀ Lé Mósè, Má Tẹ̀ Lé Fáráò (Hébérù 11:24-26)

    • • Tẹ̀ Lé Àwọn Ọmọ Ẹ̀yìn Jésù, Má Tẹ̀ Lé Àwọn Farisí (Ìṣe 5:29)

  • 4:15 Báwo Lo Ṣe Lè ‘Máa Dán Ara Rẹ Wò Bóyá O Wà Nínú Ìgbàgbọ́’? (2 Kọ́ríńtì 13:5, 11)

  • 4:50 Orin 119 àti Àdúrà Ìparí

    Yorùbá Publications (1987-2025)
    Jáde
    Wọlé
    • Yorùbá
    • Fi Ráńṣẹ́
    • Èyí tí mo fẹ́ràn jù
    • Copyright © 2025 Watch Tower Bible and Tract Society of Pennsylvania
    • Àdéhùn Nípa Lílò
    • Òfin
    • Ètò Nípa Ìsọfúnni Rẹ
    • JW.ORG
    • Wọlé
    Fi Ráńṣẹ́