ÀKÁ ÌWÉ ORÍ ÍNTÁNẸ́Ẹ̀TÌ ti Watchtower
ÀKÁ ÌWÉ ORÍ ÍŃTÁNẸ́Ẹ̀TÌ
ti Watchtower
Yorùbá
ọ́
  • ẹ
  • ọ
  • ṣ
  • ń
  • ẹ́
  • ẹ̀
  • ọ́
  • ọ̀
  • BÍBÉLÌ
  • ÌTẸ̀JÁDE
  • ÌPÀDÉ
  • CO-pgm22 ojú ìwé 4-5
  • Saturday

Kò sí fídíò kankan ní apá yìí.

Má bínú, fídíò yìí kò jáde.

  • Saturday
  • Ìtòlẹ́sẹẹsẹ Àpéjọ Agbègbè ti Ọdún 2022
  • Àpilẹ̀kọ Míì Tó Jọ ọ́
  • Sunday
    Ìtòlẹ́sẹẹsẹ Àpéjọ Agbègbè ti Ọdún 2022
  • Friday
    Ìtòlẹ́sẹẹsẹ Àpéjọ Agbègbè ti Ọdún 2022
  • Friday
    Ìtòlẹ́sẹẹsẹ Àpéjọ Agbègbè ti Ọdún 2024
  • Saturday
    Ìtòlẹ́sẹẹsẹ Àpéjọ Àgbègbè ti Ọdún 2021
Àwọn Míì
Ìtòlẹ́sẹẹsẹ Àpéjọ Agbègbè ti Ọdún 2022
CO-pgm22 ojú ìwé 4-5
Àwọ̀ búlúù àti àwọ̀ ewé.

Saturday

“Ẹ sa gbogbo ipá yín kó lè bá yín . . . láìní èérí àti àbààwọ́n àti ní àlàáfíà”​—2 Pétérù 3:14

ÀÁRỌ̀

  • 9:20 Fídíò Orin

  • 9:30 Orin 58 àti Àdúrà

  • 9:40 ÀPÍNSỌ ÀSỌYÉ: Múra Tán Láti Kéde “Ìhìn Rere Àlàáfíà”

    • • Jẹ́ Kí Iná Ìtara Ẹ Máa Jó (Róòmù 1:14, 15)

    • • Múra Sílẹ̀ Dáadáa (2 Tímótì 2:15)

    • • Máa Lo Àǹfààní Tó Bá Yọ (Jòhánù 4:6, 7, 9, 25, 26)

    • • Pa Dà Lọ Sọ́dọ̀ Àwọn Tó Nífẹ̀ẹ́ Sọ́rọ̀ Ẹ (1 Kọ́ríńtì 3:6)

    • • Ran Àwọn Tó Ò Ń Kọ́ Lẹ́kọ̀ọ́ Lọ́wọ́ Kí Wọ́n Lè Túbọ̀ Sún Mọ́ Jèhófà (Hébérù 6:1)

  • 10:40 Ẹ̀yin Ọ̀dọ́​—Ẹ Fi Ayé Yín Ṣe Ohun Táá Jẹ́ Kí Ọkàn Yín Balẹ̀! (Mátíù 6:33; Lúùkù 7:35; Jémíìsì 1:4)

  • 11:00 Orin 135 àti Ìfilọ̀

  • 11:10 FÍDÍÒ: Ọkàn Àwọn Ará Wa Balẹ̀ Bí Wọ́n Tiẹ̀ Ń Dojú Kọ . . .

    • • Àtakò

    • • Àìsàn

    • • Ìṣòro Àìlówó Lọ́wọ́

    • • Àjálù

  • 11:45 ÌRÌBỌMI: Ẹ Máa Rìn “ní Ọ̀nà Àlàáfíà” (Lúùkù 1:79; 2 Kọ́ríńtì 4:16-18; 13:11)

  • 12:15 Orin 54 àti Àkókò Ìsinmi

Ọ̀SÁN

  • 1:35 Fídíò Orin

  • 1:45 Orin 29

  • 1:50 ÀPÍNSỌ ÀSỌYÉ: Ẹ Yẹra fún Ohun Tó Lè Ba Àlàáfíà Jẹ́

    • • Kéèyàn Máa Fọ́nnu (Éfésù 4:22; 1 Kọ́ríńtì 4:7)

    • • Ìlara (Fílípì 2:3, 4)

    • • Àìṣòótọ́ (Éfésù 4:25)

    • • Òfófó Tó Ń Pani Lára (Òwe 15:28)

    • • Ìbínú Òdì (Jémíìsì 1:19)

  • 2:45 FÍDÍÒ: Jèhófà Ń Darí Wa ní Ọ̀nà Àlàáfíà​—Apá 1 (Àìsáyà 48:17, 18)

  • 3:15 Orin 130 àti Ìfilọ̀

  • 3:25 ÀPÍNSỌ ÀSỌYÉ: ‘Máa Wá Àlàáfíà, Kó O sì Máa Lépa Rẹ̀’ . . .

    • • Má Tètè Máa Bínú (Òwe 19:11; Oníwàásù 7:9; 1 Pétérù 3:11)

    • • Máa Tọrọ Àforíjì (Mátíù 5:23, 24; Ìṣe 23:3-5)

    • • Máa Dárí Jini Fàlàlà (Kólósè 3:13)

    • • Máa Sọ Ohun Tó Máa Ṣe Àwọn Èèyàn Láǹfààní (Òwe 12:18; 18:21)

  • 4:15 Má Ṣe Jẹ́ Kí Àlàáfíà Tó Wà Láàárìn Wa Bà Jẹ́ (Éfésù 4:1-6)

  • 4:50 Orin 113 àti Àdúrà Ìparí

    Yorùbá Publications (1987-2025)
    Jáde
    Wọlé
    • Yorùbá
    • Fi Ráńṣẹ́
    • Èyí tí mo fẹ́ràn jù
    • Copyright © 2025 Watch Tower Bible and Tract Society of Pennsylvania
    • Àdéhùn Nípa Lílò
    • Òfin
    • Ètò Nípa Ìsọfúnni Rẹ
    • JW.ORG
    • Wọlé
    Fi Ráńṣẹ́