ÀKÁ ÌWÉ ORÍ ÍNTÁNẸ́Ẹ̀TÌ ti Watchtower
ÀKÁ ÌWÉ ORÍ ÍŃTÁNẸ́Ẹ̀TÌ
ti Watchtower
Yorùbá
ọ́
  • ẹ
  • ọ
  • ṣ
  • ń
  • ẹ́
  • ẹ̀
  • ọ́
  • ọ̀
  • BÍBÉLÌ
  • ÌTẸ̀JÁDE
  • ÌPÀDÉ
  • CO-pgm23 ojú ìwé 4-5
  • Saturday

Kò sí fídíò kankan ní apá yìí.

Má bínú, fídíò yìí kò jáde.

  • Saturday
  • Ìtòlẹ́sẹẹsẹ Àpéjọ Agbègbè ti Ọdún 2023
  • Àpilẹ̀kọ Míì Tó Jọ ọ́
  • Friday
    Ìtòlẹ́sẹẹsẹ Àpéjọ Agbègbè ti Ọdún 2023
  • Saturday
    Ìtòlẹ́sẹẹsẹ Àpéjọ Àgbègbè ti Ọdún 2021
  • Saturday
    Ìtòlẹ́sẹẹsẹ Àpéjọ Àgbègbè ti Ọdún 2017
  • Sunday
    Ìtòlẹ́sẹẹsẹ Àpéjọ Agbègbè ti Ọdún 2024
Àwọn Míì
Ìtòlẹ́sẹẹsẹ Àpéjọ Agbègbè ti Ọdún 2023
CO-pgm23 ojú ìwé 4-5
Àwòrán: Àwọn nǹkan tá a máa gbádùn lọ́jọ́ Saturday. 1. Ìdílé kan ń bá ara wọn sọ̀rọ̀ lórí Íńtánẹ́ẹ̀tì, inú wọn sì ń dùn. 2. Ọba kan ń ronú. 3. Bàbá kan àti ọmọ ẹ̀ wà lọ́jà.

Saturday

“Ẹ máa mú sùúrù fún gbogbo èèyàn”​—1 Tẹsalóníkà 5:14

Àárọ̀

  • 9:20 Fídíò Orin

  • 9:30 Orin 58 àti Àdúrà

  • 9:40 ÀPÍNSỌ ÀSỌYÉ: ‘À Ń Dámọ̀ràn Ara Wa Bí Òjíṣẹ́ Ọlọ́run . . . Bá A Ṣe Ń Mú Sùúrù’

    • • Tá A Bá Ń Wàásù (Ìṣe 26:29; 2 Kọ́ríńtì 6:4, 6)

    • • Tá A Bá Ń Kọ́ni (Jòhánù 16:12)

    • • Tá A Bá Ń Fún Ara Wa Níṣìírí (1 Tẹsalóníkà 5:11)

    • • Tá A Bá Jẹ́ Alàgbà (2 Tímótì 4:2)

  • 10:30 Ẹ Máa Mú Sùúrù Fáwọn Èèyàn Bí Jèhófà Ṣe Ń Mú Sùúrù fún Yín! (Mátíù 7:1, 2; 18:23-35)

  • 10:50 Orin 138 àti Ìfilọ̀

  • 11:00 ÀPÍNSỌ ÀSỌYÉ: ‘Ẹ Ní Sùúrù, Kí Ẹ sì Máa Fara Dà Á fún Ara Yín Nínú Ìfẹ́’

    • • Àwọn Mọ̀lẹ́bí Wa tí Kò Sin Jèhófà (Kólósè 4:6)

    • • Ọkọ Tàbí Aya Rẹ (Òwe 19:11)

    • • Àwọn Ọmọ Rẹ (2 Tímótì 3:14)

    • • Àwọn Àgbàlagbà Tàbí Àwọn tí Ara Wọn Ò Le Nínú Ìdílé (Hébérù 13:16)

  • 11:45 ÌRÌBỌMI: Sùúrù Jèhófà Máa Jẹ́ Ká Rí Ìgbàlà! (2 Pétérù 3:13-15)

  • 12:15 Orin 75 àti Àkókò Ìsinmi

Ọ̀sán

  • 1:35 Fídíò Orin

  • 1:45 Orin 106

  • 1:50 Kí Nìdí Tó Fi Yẹ Ká Ṣọ́ra fún Ìgbádùn Ojú Ẹsẹ̀? (1 Tẹsalóníkà 4:3-5; 1 Jòhánù 2:17)

  • 2:15 ÀPÍNSỌ ÀSỌYÉ: ‘Ó Sàn Kéèyàn Ní Sùúrù Ju Pé Kó Máa Gbéra Ga’

    • • Tẹ̀ Lé Àpẹẹrẹ Ébẹ́lì, Má Tẹ̀ Lé ti Ádámù (Oníwàásù 7:8)

    • • Tẹ̀ Lé Àpẹẹrẹ Jékọ́bù, Má Tẹ̀ Lé ti Ísọ̀ (Hébérù 12:16)

    • • Tẹ̀ Lé Àpẹẹrẹ Mósè, Má Tẹ̀ Lé ti Kórà (Nọ́ńbà 16:9, 10)

    • • Tẹ̀ Lé Àpẹẹrẹ Sámúẹ́lì, Má Tẹ̀ Lé ti Sọ́ọ̀lù (1 Sámúẹ́lì 15:22)

    • • Tẹ̀ Lé Àpẹẹrẹ Jónátánì, Má Tẹ̀ Lé ti Ábúsálómù (1 Sámúẹ́lì 23:16-18)

  • 3:15 Orin 87 àti Ìfilọ̀

  • 3:25 FÍDÍÒ: “Fi Ọ̀nà Rẹ Lé Jèhófà Lọ́wọ́”​—Apá 1 (Sáàmù 37:5)

  • 3:55 “Nígbà Tí Wọ́n Ń Ṣe Inúnibíni sí Wa, À Ń Fara Dà Á Pẹ̀lú Sùúrù” (1 Kọ́ríńtì 4:12; Róòmù 12:14, 21)

  • 4:30 Orin 79 àti Àdúrà Ìparí

    Yorùbá Publications (1987-2025)
    Jáde
    Wọlé
    • Yorùbá
    • Fi Ráńṣẹ́
    • Èyí tí mo fẹ́ràn jù
    • Copyright © 2025 Watch Tower Bible and Tract Society of Pennsylvania
    • Àdéhùn Nípa Lílò
    • Òfin
    • Ètò Nípa Ìsọfúnni Rẹ
    • JW.ORG
    • Wọlé
    Fi Ráńṣẹ́