ÀKÁ ÌWÉ ORÍ ÍNTÁNẸ́Ẹ̀TÌ ti Watchtower
ÀKÁ ÌWÉ ORÍ ÍŃTÁNẸ́Ẹ̀TÌ
ti Watchtower
Yorùbá
ọ́
  • ẹ
  • ọ
  • ṣ
  • ń
  • ẹ́
  • ẹ̀
  • ọ́
  • ọ̀
  • BÍBÉLÌ
  • ÌTẸ̀JÁDE
  • ÌPÀDÉ
  • mwb19 July ojú ìwé 3
  • “Ẹ Máa Fún Ara Yín Níṣìírí, Kí Ẹ sì Máa Gbé Ara Yín Ró”

Kò sí fídíò kankan ní apá yìí.

Má bínú, fídíò yìí kò jáde.

  • “Ẹ Máa Fún Ara Yín Níṣìírí, Kí Ẹ sì Máa Gbé Ara Yín Ró”
  • Ìgbésí Ayé àti Iṣẹ́ Òjíṣẹ́ Kristẹni—Ìwé Ìpàdé—2019
  • Àpilẹ̀kọ Míì Tó Jọ ọ́
  • ‘Ẹ Máa Gba Ara Yín Níyànjú Lẹ́nì Kìíní-Kejì Lójoojúmọ́’
    Ilé Ìṣọ́ Tí Ń Kéde Ìjọba Jehofa (Ẹ̀dà Tó Wà fún Ìkẹ́kọ̀ọ́)—2016
  • Ìsinsìnyí Ló Yẹ Ká Máa Fún Ara Wa Níṣìírí Ju ti Ìgbàkigbà Rí Lọ
    Ilé Ìṣọ́ Tí Ń Kéde Ìjọba Jehofa (Ẹ̀dà Tó Wà fún Ìkẹ́kọ̀ọ́)—2018
  • Ẹ Máa Gba Ara Yín Níyànjú
    “Fi Ayọ̀ Kọrin” sí Jèhófà
  • Ká Máa Fún Ara Wa Níṣìírí
    Kọrin sí Jèhófà
Àwọn Míì
Ìgbésí Ayé àti Iṣẹ́ Òjíṣẹ́ Kristẹni—Ìwé Ìpàdé—2019
mwb19 July ojú ìwé 3
Arábìnrin àgbàlagbà kan ń fún ọ̀dọ́bìnrin méjì ní nǹkan tí wọ́n máa mu

ÀWỌN ÌṢÚRA INÚ Ọ̀RỌ̀ ỌLỌ́RUN | 1 TẸSALÓNÍKÀ 1-5

“Ẹ Máa Fún Ara Yín Níṣìírí, Kí Ẹ sì Máa Gbé Ara Yín Ró”

5:11-14

Gbogbo àwa Kristẹni la lè fún ẹlòmíì níṣìírí. Bí àpẹẹrẹ, ó ṣeé ṣe káwọn ará wa máa kojú “ọ̀pọ̀ àtakò,” bóyá torí àìlera tàbí àwọn ìṣòro míì, àmọ́ ìṣírí ńlá ló máa jẹ́ fún wọn tá a bá ń wá sípàdé déédéé, tá a sì ń lọ sí òde ẹ̀rí. (1Tẹ 2:2) Tá a bá ti ronú nípa wọn ṣáájú, tá a sì ṣèwádìí, ó máa rọrùn fún wa láti sọ̀rọ̀ ìtùnú fún àwọn ará wa tó nílò ìṣírí.

Ibo lo ti lè rí àwọn ìsọfúnni tó máa ràn ẹ́ lọ́wọ́ láti fún ẹni tó ní ìṣòro níṣìírí?

Ta lo máa fẹ́ fún níṣìírí nínú ìjọ yín?

    Yorùbá Publications (1987-2025)
    Jáde
    Wọlé
    • Yorùbá
    • Fi Ráńṣẹ́
    • Èyí tí mo fẹ́ràn jù
    • Copyright © 2025 Watch Tower Bible and Tract Society of Pennsylvania
    • Àdéhùn Nípa Lílò
    • Òfin
    • Ètò Nípa Ìsọfúnni Rẹ
    • JW.ORG
    • Wọlé
    Fi Ráńṣẹ́