ÀKÁ ÌWÉ ORÍ ÍNTÁNẸ́Ẹ̀TÌ ti Watchtower
ÀKÁ ÌWÉ ORÍ ÍŃTÁNẸ́Ẹ̀TÌ
ti Watchtower
Yorùbá
ọ́
  • ẹ
  • ọ
  • ṣ
  • ń
  • ẹ́
  • ẹ̀
  • ọ́
  • ọ̀
  • BÍBÉLÌ
  • ÌTẸ̀JÁDE
  • ÌPÀDÉ
  • mwb19 September ojú ìwé 3
  • “Òjìji Àwọn Nǹkan Rere Tó Ń Bọ̀”

Kò sí fídíò kankan ní apá yìí.

Má bínú, fídíò yìí kò jáde.

  • “Òjìji Àwọn Nǹkan Rere Tó Ń Bọ̀”
  • Ìgbésí Ayé àti Iṣẹ́ Òjíṣẹ́ Kristẹni—Ìwé Ìpàdé—2019
  • Àpilẹ̀kọ Míì Tó Jọ ọ́
  • Ohun Tó Ṣe Pàtàkì Jù Lọ Nínú Àgọ́ Ìjọsìn
    Ìgbésí Ayé àti Iṣẹ́ Òjíṣẹ́ Kristẹni—Ìwé Ìpàdé—2020
  • Mọyì Àǹfààní Tó O Ní Láti Jọ́sìn Jèhófà Nínú Tẹ́ńpìlì Tẹ̀mí
    Ilé Ìṣọ́ Tí Ń Kéde Ìjọba Jehofa (Tó Wà fún Ìkẹ́kọ̀ọ́)—2023
  • Wọ́n Kọ́ Àgọ́ Ìjọsìn
    Àwọn Ẹ̀kọ́ Tó O Lè Kọ́ Látinú Bíbélì
  • “A Rà Yín Pẹlu Iye-owo Kan”
    Ilé-Ìṣọ́nà Tí Ń Kéde Ìjọba Jehofa—1991
Àwọn Míì
Ìgbésí Ayé àti Iṣẹ́ Òjíṣẹ́ Kristẹni—Ìwé Ìpàdé—2019
mwb19 September ojú ìwé 3

ÀWỌN ÌṢÚRA INÚ Ọ̀RỌ̀ ỌLỌ́RUN | HÉBÉRÙ 9-10

“Òjìji Àwọn Nǹkan Rere Tó Ń Bọ̀”

9:12-14, 24-26; 10:1-4

Àgọ́ ìjọsìn ṣàpẹẹrẹ ètò tí Ọlọ́run ṣe láti gba aráyé sílẹ̀ lọ́wọ́ ẹ̀ṣẹ̀ nípasẹ̀ ìràpadà. Nínú àwòrán yìí, a máa rí nǹkan mẹ́rin tó wà nínú àgọ́ ìjọsìn àtohun tí wọ́n ṣàpẹẹrẹ, kọ nọ́ńbà ohun tí ọ̀kọ̀ọ̀kan wọn dúró fún síwájú rẹ̀.

Bí àgọ́ ìjọsìn inú lọ́hùn-⁠ún ṣe rí
  1. Aṣọ ìkélé

  2. Àlùfáà Àgbà ń wọ́n ẹ̀jẹ̀ ẹran tí wọ́n fi rúbọ níwájú Àpótí Jèhófà

  3. Ibi Mímọ́ Jù Lọ

  4. Àlùfáà àgbà

  • Jésù

  • Ọ̀run

  • Gbígbé ìtóye ẹbọ lọ fún Jèhófà

  • Ara Kristi

    Yorùbá Publications (1987-2025)
    Jáde
    Wọlé
    • Yorùbá
    • Fi Ráńṣẹ́
    • Èyí tí mo fẹ́ràn jù
    • Copyright © 2025 Watch Tower Bible and Tract Society of Pennsylvania
    • Àdéhùn Nípa Lílò
    • Òfin
    • Ètò Nípa Ìsọfúnni Rẹ
    • JW.ORG
    • Wọlé
    Fi Ráńṣẹ́