ÀKÁ ÌWÉ ORÍ ÍNTÁNẸ́Ẹ̀TÌ ti Watchtower
ÀKÁ ÌWÉ ORÍ ÍŃTÁNẸ́Ẹ̀TÌ
ti Watchtower
Yorùbá
ọ́
  • ẹ
  • ọ
  • ṣ
  • ń
  • ẹ́
  • ẹ̀
  • ọ́
  • ọ̀
  • BÍBÉLÌ
  • ÌTẸ̀JÁDE
  • ÌPÀDÉ
  • mwb19 September ojú ìwé 5
  • Ìbáwí Máa Ń Fi Hàn Pé Jèhófà Nífẹ̀ẹ́ Wa

Kò sí fídíò kankan ní apá yìí.

Má bínú, fídíò yìí kò jáde.

  • Ìbáwí Máa Ń Fi Hàn Pé Jèhófà Nífẹ̀ẹ́ Wa
  • Ìgbésí Ayé àti Iṣẹ́ Òjíṣẹ́ Kristẹni—Ìwé Ìpàdé—2019
  • Àpilẹ̀kọ Míì Tó Jọ ọ́
  • Ìfẹ́ Ló Ń Mú Kí Jèhófà Bá Wa Wí
    Ìgbésí Ayé àti Iṣẹ́ Òjíṣẹ́ Kristẹni—Ìwé Ìpàdé—2021
  • Mímọrírì Ìdí Tá A Fi Ń Báni Wí
    Ilé Ìṣọ́ Tí Ń Kéde Ìjọba Jehofa—2003
  • Ìfẹ́ Ló Ń Mú Ká Fara Mọ́ Ìbáwí Jèhófà
    Ìgbésí Ayé àti Iṣẹ́ Òjíṣẹ́ Kristẹni—Ìwé Ìpàdé—2020
  • Báwo Ni Ìbáwí Ṣe Ń Fi Hàn Pé Jèhófà Nífẹ̀ẹ́ Wa?
    Ilé Ìṣọ́ Tí Ń Kéde Ìjọba Jehofa (Ẹ̀dà Tó Wà fún Ìkẹ́kọ̀ọ́)—2018
Àwọn Míì
Ìgbésí Ayé àti Iṣẹ́ Òjíṣẹ́ Kristẹni—Ìwé Ìpàdé—2019
mwb19 September ojú ìwé 5

ÀWỌN ÌṢÚRA INÚ Ọ̀RỌ̀ ỌLỌ́RUN | HÉBÉRÙ 12-13

Ìbáwí Máa Ń Fi Hàn Pé Jèhófà Nífẹ̀ẹ́ Wa

12:5-7, 11

Ìyá kan ń ka ìwé “Kẹ́kọ̀ọ́ Lọ́dọ̀ Olùkọ́ Ńlá Náà” sétí ọmọbìnrin rẹ̀

Ohun tí ìbáwí túmọ̀ sí ni pé kí wọ́n na ẹnì kan, kí wọ́n fún un ní ìtọ́ni tàbí kí wọ́n kọ́ ọ lẹ́kọ̀ọ́. Bí bàbá onífẹ̀ẹ́ kan ṣe máa bá ọmọ rẹ̀ wí, bẹ́ẹ̀ ni Jèhófà ṣe máa ń bá wa wí. Onírúurú ọ̀nà ni Jèhófà máa ń gbà bá wa wí, ó lè ṣe bẹ́ẹ̀ . . .

  • Tá a bá ń kà Bíbélì, tá à ń dá kẹ́kọ̀ọ́, tá à ń lọ sípàdé, tá a sì ń ṣàṣàrò

  • Tí Kristẹni míì bá bá wa wí

  • Tá a bá ń jìyà àbájáde àṣìṣe wa

  • Tí ìgbìmọ̀ ìgbẹ́jọ́ bá bá ẹnì kan wí tàbí tí wọ́n yọ ọ́ lẹ́gbẹ́

  • Nígbà tó bá fàyè gba àdánwò tàbí inúnibíni​—w15 9/15 21 ¶13; it-1 629

    Yorùbá Publications (1987-2025)
    Jáde
    Wọlé
    • Yorùbá
    • Fi Ráńṣẹ́
    • Èyí tí mo fẹ́ràn jù
    • Copyright © 2025 Watch Tower Bible and Tract Society of Pennsylvania
    • Àdéhùn Nípa Lílò
    • Òfin
    • Ètò Nípa Ìsọfúnni Rẹ
    • JW.ORG
    • Wọlé
    Fi Ráńṣẹ́