ÀKÁ ÌWÉ ORÍ ÍNTÁNẸ́Ẹ̀TÌ ti Watchtower
ÀKÁ ÌWÉ ORÍ ÍŃTÁNẸ́Ẹ̀TÌ
ti Watchtower
Yorùbá
ọ́
  • ẹ
  • ọ
  • ṣ
  • ń
  • ẹ́
  • ẹ̀
  • ọ́
  • ọ̀
  • BÍBÉLÌ
  • ÌTẸ̀JÁDE
  • ÌPÀDÉ
  • mwb20 September ojú ìwé 2
  • Má Ṣe Tẹ̀ Lé Ọ̀pọ̀ Èèyàn

Kò sí fídíò kankan ní apá yìí.

Má bínú, fídíò yìí kò jáde.

  • Má Ṣe Tẹ̀ Lé Ọ̀pọ̀ Èèyàn
  • Ìgbésí Ayé àti Iṣẹ́ Òjíṣẹ́ Kristẹni—Ìwé Ìpàdé—2020
  • Àpilẹ̀kọ Míì Tó Jọ ọ́
  • Jèhófà Bù Kún Ogunlọ́gọ̀ Èèyàn Tí Ẹnikẹ́ni Kò Lè Kà
    Ìgbésí Ayé àti Iṣẹ́ Òjíṣẹ́ Kristẹni—Ìwé Ìpàdé—2019
  • Ṣe Tán Láti Dárí Jini
    Ìgbésí Ayé àti Iṣẹ́ Òjíṣẹ́ Kristẹni—Ìwé Ìpàdé—2018
  • Ogunlọ́gọ̀ Ńlá
    Ìṣípayá—Ìparí Rẹ̀ Ológo Kù sí Dẹ̀dẹ̀!
  • ‘Wò Ó! Ogunlọ́gọ̀ Èèyàn’
    Ilé Ìṣọ́ Tí Ń Kéde Ìjọba Jehofa (Ẹ̀dà Tó Wà fún Ìkẹ́kọ̀ọ́)—2019
Àwọn Míì
Ìgbésí Ayé àti Iṣẹ́ Òjíṣẹ́ Kristẹni—Ìwé Ìpàdé—2020
mwb20 September ojú ìwé 2
Àwọn tó ń lọ lójú ọ̀nà ń ka ìròyìn látorí fóònù wọn, àwọn mí ì sì ń gbọ́ ìròyìn lórí tẹlifíṣọ̀n.

ÀWỌN ÌṢÚRA INÚ Ọ̀RỌ̀ ỌLỌ́RUN | Ẹ́KÍSÓDÙ 23-24

Má Ṣe Tẹ̀ Lé Ọ̀pọ̀ Èèyàn

23:​1-3

Jèhófà kìlọ̀ fún àwọn adájọ́ tàbí ẹnikẹ́ni tó bá wá jẹ́rìí pé wọn ò gbọ́dọ̀ jẹ́ káwọn èèyàn mú kí wọ́n jẹ́rìí èké tàbí kí wọ́n gbé ẹ̀bi fún aláre. Àwa náà lè lo ìlànà yìí nínú àwọn nǹkan tá à ń ṣe nígbèésí ayé wa. Ayé yìí ń wá bí wọ́n á ṣe mú káwa Kristẹni máa ronú lọ́nà tí kò bá ìfẹ́ Jèhófà mu.​—Ro 12:2.

Kí nìdí tí kò fi yẹ ká máa tẹ̀ lé ọ̀pọ̀ èèyàn nígbà tá a bá

  • gbọ́ ọ̀rọ̀ kan tó ń jà ràn-ìn tá ò sì mọ̀ bóyá òótọ́ ni?

  • fẹ́ yan irú aṣọ tá a máa wọ̀, irun tá a máa ṣe tàbí eré ìnàjú tá a máa wò?

  • ń ronú nípa ojú tá a fi ń wo àwọn tí kì í ṣe ọmọ ilẹ̀ wa, àwọn tálákà tàbí àwọn olówó?

    Yorùbá Publications (1987-2025)
    Jáde
    Wọlé
    • Yorùbá
    • Fi Ráńṣẹ́
    • Èyí tí mo fẹ́ràn jù
    • Copyright © 2025 Watch Tower Bible and Tract Society of Pennsylvania
    • Àdéhùn Nípa Lílò
    • Òfin
    • Ètò Nípa Ìsọfúnni Rẹ
    • JW.ORG
    • Wọlé
    Fi Ráńṣẹ́