ÀKÁ ÌWÉ ORÍ ÍNTÁNẸ́Ẹ̀TÌ ti Watchtower
ÀKÁ ÌWÉ ORÍ ÍŃTÁNẸ́Ẹ̀TÌ
ti Watchtower
Yorùbá
ọ́
  • ẹ
  • ọ
  • ṣ
  • ń
  • ẹ́
  • ẹ̀
  • ọ́
  • ọ̀
  • BÍBÉLÌ
  • ÌTẸ̀JÁDE
  • ÌPÀDÉ
  • mwb21 March ojú ìwé 10
  • “Èmi Ni . . . Ogún Rẹ”

Kò sí fídíò kankan ní apá yìí.

Má bínú, fídíò yìí kò jáde.

  • “Èmi Ni . . . Ogún Rẹ”
  • Ìgbésí Ayé àti Iṣẹ́ Òjíṣẹ́ Kristẹni—Ìwé Ìpàdé—2021
  • Àpilẹ̀kọ Míì Tó Jọ ọ́
  • Bí Jèhófà Ṣe Ń Darí Àwọn Èèyàn Rẹ̀
    Ìgbésí Ayé àti Iṣẹ́ Òjíṣẹ́ Kristẹni—Ìwé Ìpàdé—2021
  • Má Ṣe Máa Gbéra Ga, Má sì Dá Ara Rẹ Lójú Jù
    Ìgbésí Ayé àti Iṣẹ́ Òjíṣẹ́ Kristẹni—Ìwé Ìpàdé—2021
  • Máa Wádìí Lọ́dọ̀ Jèhófà
    Ìgbésí Ayé àti Iṣẹ́ Òjíṣẹ́ Kristẹni—Ìwé Ìpàdé—2022
  • Jèhófà Ni Ìpín Mi
    Ilé Ìṣọ́ Tí Ń Kéde Ìjọba Jehofa—2011
Àwọn Míì
Ìgbésí Ayé àti Iṣẹ́ Òjíṣẹ́ Kristẹni—Ìwé Ìpàdé—2021
mwb21 March ojú ìwé 10

ÀWỌN ÌṢÚRA INÚ Ọ̀RỌ̀ ỌLỌ́RUN

“Èmi Ni . . . Ogún Rẹ”

Àǹfààní iṣẹ́ ìsìn tó ṣàrà ọ̀tọ̀ ni Jèhófà fún àwọn àlùfáà àtàwọn ọmọ Léfì (Nọ 18:​6, 7)

Ẹ̀yà Léfì ò ní ilẹ̀ kankan tí wọ́n lè jogún, Jèhófà ni ogún wọn (Nọ 18:​20, 24; w11 9/15 13 ¶9)

Àwọn ọmọ Ísírẹ́lì máa ń fún àwọn ọmọ Léfì àtàwọn àlùfáà ní ìdá mẹ́wàá (Nọ 18:​21, 26, 27; w11 9/15 7 ¶4)

Jèhófà ṣèlérí fáwọn àlùfáà àtàwọn ọmọ Léfì pé òun á máa pèsè gbogbo ohun tí wọ́n nílò. Ó dájú pé Jèhófà ò ní fi àwa náà sílẹ̀ tá a bá yááfì àwọn nǹkan kan ká lè sìn ín.

Àwòrán: Jèhófà ń pèsè fún àwọn èèyàn rẹ̀. 1. Arábìnrin kan ń fi owó sínú àpò ìwé. 2. Ó fi àpò ìwé náà há ẹnu ọ̀nà òbí anìkàntọ́mọ kan. 3. Òbí anìkàntọ́mọ kan gbá ọmọ rẹ̀ mọ́ra, ó sì ń wo owó tó wà nínú àpò ìwé.
    Yorùbá Publications (1987-2025)
    Jáde
    Wọlé
    • Yorùbá
    • Fi Ráńṣẹ́
    • Èyí tí mo fẹ́ràn jù
    • Copyright © 2025 Watch Tower Bible and Tract Society of Pennsylvania
    • Àdéhùn Nípa Lílò
    • Òfin
    • Ètò Nípa Ìsọfúnni Rẹ
    • JW.ORG
    • Wọlé
    Fi Ráńṣẹ́