ÀKÁ ÌWÉ ORÍ ÍNTÁNẸ́Ẹ̀TÌ ti Watchtower
ÀKÁ ÌWÉ ORÍ ÍŃTÁNẸ́Ẹ̀TÌ
ti Watchtower
Yorùbá
ọ́
  • ẹ
  • ọ
  • ṣ
  • ń
  • ẹ́
  • ẹ̀
  • ọ́
  • ọ̀
  • BÍBÉLÌ
  • ÌTẸ̀JÁDE
  • ÌPÀDÉ
  • mwb22 September ojú ìwé 6
  • Kí Nìdí Tó Fi Yẹ Ká Ní Ìtẹ́lọ́rùn, Ká sì Mọ̀wọ̀n Ara Wa?

Kò sí fídíò kankan ní apá yìí.

Má bínú, fídíò yìí kò jáde.

  • Kí Nìdí Tó Fi Yẹ Ká Ní Ìtẹ́lọ́rùn, Ká sì Mọ̀wọ̀n Ara Wa?
  • Ìgbésí Ayé àti Iṣẹ́ Òjíṣẹ́ Kristẹni—Ìwé Ìpàdé—2022
  • Àpilẹ̀kọ Míì Tó Jọ ọ́
  • Bá A Ṣe Lè Rí Ìbùkún Jèhófà
    Ìgbésí Ayé àti Iṣẹ́ Òjíṣẹ́ Kristẹni—Ìwé Ìpàdé—2021
  • “Lójú Ẹsẹ̀, Mo Gbàdúrà”
    Ìgbésí Ayé àti Iṣẹ́ Òjíṣẹ́ Kristẹni—Ìwé Ìpàdé—2023
  • Òótọ́ Làwọn Ìtàn Bíbélì, Kì Í Ṣe Àròsọ
    Ìgbésí Ayé àti Iṣẹ́ Òjíṣẹ́ Kristẹni—Ìwé Ìpàdé—2023
  • Ó Sàn Kéèyàn Lẹ́mìí Ìrẹ̀lẹ̀ Ju Kó Jẹ́ Agbéraga
    Ìgbésí Ayé àti Iṣẹ́ Òjíṣẹ́ Kristẹni—Ìwé Ìpàdé—2021
Àwọn Míì
Ìgbésí Ayé àti Iṣẹ́ Òjíṣẹ́ Kristẹni—Ìwé Ìpàdé—2022
mwb22 September ojú ìwé 6

ÀWỌN ÌṢÚRA INÚ Ọ̀RỌ̀ ỌLỌ́RUN

Kí Nìdí Tó Fi Yẹ Ká Ní Ìtẹ́lọ́rùn, Ká sì Mọ̀wọ̀n Ara Wa?

Wólìí Ọlọ́run kan kọ̀ láti gba àwọn ẹ̀bùn iyebíye tí Jèróbóámù fẹ́ fún un (1Ọb 13:7-10; w08 8/15 8 ¶4)

Nígbà tó yá, wòlíì Ọlọ́run yìí ṣàìgbọràn sí àṣẹ Jèhófà (1Ọb 13:14-19; w08 8/15 11 ¶15)

Wòlíì náà pàdánù ẹ̀mí ẹ̀ torí pé ó ṣàìgbọràn sí Jèhófà (1Ọb 13:20-22; w08 8/15 9 ¶10)

Tọkọtaya kan ń sọ̀rọ̀ nípa bí wọ́n á ṣe ná owó tó ń wọlé, àwọn ọmọ wọn ń ṣeré lẹ́yìnkùlé.

Tá a bá jẹ́ kí ohun tá a ní tẹ́ wa lọ́rùn, tá a sì ń jẹ́ kí Jèhófà tọ́ wa sọ́nà ká tó ṣèpinnu, a ò ní tọrùn bọ ọ̀pọ̀ ìṣòro.—1Ti 6:8-10.

BI ARA RẸ PÉ: ‘Báwo ni mo ṣe lè fi hàn pé àwọn nǹkan tí mo ní tẹ́ mi lọ́rùn? Báwo ni mo ṣe lè fi hàn pé mo mọ̀wọ̀n ara mi tí mo bá fẹ́ ṣèpinnu?’—Owe 3:5; 11:2.

    Yorùbá Publications (1987-2025)
    Jáde
    Wọlé
    • Yorùbá
    • Fi Ráńṣẹ́
    • Èyí tí mo fẹ́ràn jù
    • Copyright © 2025 Watch Tower Bible and Tract Society of Pennsylvania
    • Àdéhùn Nípa Lílò
    • Òfin
    • Ètò Nípa Ìsọfúnni Rẹ
    • JW.ORG
    • Wọlé
    Fi Ráńṣẹ́