ÀKÁ ÌWÉ ORÍ ÍNTÁNẸ́Ẹ̀TÌ ti Watchtower
ÀKÁ ÌWÉ ORÍ ÍŃTÁNẸ́Ẹ̀TÌ
ti Watchtower
Yorùbá
ọ́
  • ẹ
  • ọ
  • ṣ
  • ń
  • ẹ́
  • ẹ̀
  • ọ́
  • ọ̀
  • BÍBÉLÌ
  • ÌTẸ̀JÁDE
  • ÌPÀDÉ
  • mwb23 November ojú ìwé 7
  • Ẹ “Jẹ́ Kí Àwọn Nǹkan Tó Wà Báyìí Tẹ́ Yín Lọ́rùn”

Kò sí fídíò kankan ní apá yìí.

Má bínú, fídíò yìí kò jáde.

  • Ẹ “Jẹ́ Kí Àwọn Nǹkan Tó Wà Báyìí Tẹ́ Yín Lọ́rùn”
  • Ìgbésí Ayé àti Iṣẹ́ Òjíṣẹ́ Kristẹni—Ìwé Ìpàdé—2023
  • Àpilẹ̀kọ Míì Tó Jọ ọ́
  • Ẹ Dẹ́kun Ṣíṣàníyàn
    Ìgbésí Ayé àti Iṣẹ́ Òjíṣẹ́ Kristẹni—Ìwé Ìpàdé—2018
  • Ṣé Owó Ni Gbòǹgbò Ohun Búburú Gbogbo?
    Ohun Tí Bíbélì Sọ
  • Ohun Tí Bíbélì Sọ Nípa Iṣẹ́ àti Owó
    Gbádùn Ayé Rẹ Títí Láé!—Ìjíròrò Látinú Bíbélì
  • Ṣé O Mọ Béèyàn Ṣe Ń Nítẹ̀ẹ́lọ́rùn?
    Ilé Ìṣọ́ Tí Ń Kéde Ìjọba Jehofa (Tó Wà fún Ìkẹ́kọ̀ọ́)—2025
Àwọn Míì
Ìgbésí Ayé àti Iṣẹ́ Òjíṣẹ́ Kristẹni—Ìwé Ìpàdé—2023
mwb23 November ojú ìwé 7

MÁA HÙWÀ TÓ YẸ KRISTẸNI

Ẹ “Jẹ́ Kí Àwọn Nǹkan Tó Wà Báyìí Tẹ́ Yín Lọ́rùn”

Tí owó tó ń wọlé fún wa ò bá tó nǹkan, ó lè máa ṣe wá bíi pé ká lọ́wọ́ sí àwọn ohun kan. Àwọn nǹkan náà sì lè mú ká jìnnà sí Jèhófà. Bí àpẹẹrẹ, a lè rí iṣẹ́ tó máa mówó gọbọi wọlé àmọ́ tí kò ní jẹ́ ká ráyè fáwọn nǹkan tó jẹ mọ́ ìjọsìn Ọlọ́run. Tá a bá ronú lórí Hébérù 13:​5, ó máa jẹ́ ká lè ṣèpinnu tó tọ́.

“Ẹ yẹra fún ìfẹ́ owó nínú ìgbésí ayé yín”

  • Gbàdúrà, kó o wá ronú nípa bó o ṣe máa ń ṣe tó bá ti kan ọ̀rọ̀ owó. Lẹ́yìn náà, ronú nípa àpẹẹrẹ tó ò ń fi lélẹ̀ fáwọn ọmọ rẹ.—g 11/15 6.

“Bí ẹ ṣe ń jẹ́ kí àwọn nǹkan tó wà báyìí tẹ́ yín lọ́rùn”

  • Fara balẹ̀ ronú lórí ohun tó o nílò gan-an.—w16.07 7 ¶1-2.

“Mi ò ní fi ọ́ sílẹ̀ láé, mi ò sì ní pa ọ́ tì láé”

  • Jẹ́ kó dá ẹ lójú pé Jèhófà máa pèsè àwọn ohun kòṣeémánìí fún ẹ tó o bá ń fi ire Ìjọba rẹ̀ sípò àkọ́kọ́.—w14 4/15 21 ¶17.

Àwòrán: Àwọn apá kan nínú fídíò náà “Ọkàn Àwọn Ará Wa Balẹ̀ Bí Wọ́n Tiẹ̀ Ń Dojú Kọ Ìṣòro Àìlówó Lọ́wọ́.” 1. Miguel ń po ìyẹ̀fun nítòsí àdògán ńlá kan. 2. Ó ń lọ aṣọ. 3. Ó wo ara ẹ̀ nínú dígí, ó sì rẹ́rìn-ín bó ṣe ń múra láti lọ síbiṣẹ́.

Ẹ WO FÍDÍÒ NÁÀ, ỌKÀN ÀWỌN ARÁ WA BALẸ̀ BÍ WỌ́N TIẸ̀ Ń DOJÚ KỌ ÌṢÒRO ÀÌLÓWÓ LỌ́WỌ́, KẸ́ Ẹ SÌ DÁHÙN ÌBÉÈRÈ YÌÍ:

Kí lo rí kọ́ nínú ìrírí Miguel Novoa?

    Yorùbá Publications (1987-2025)
    Jáde
    Wọlé
    • Yorùbá
    • Fi Ráńṣẹ́
    • Èyí tí mo fẹ́ràn jù
    • Copyright © 2025 Watch Tower Bible and Tract Society of Pennsylvania
    • Àdéhùn Nípa Lílò
    • Òfin
    • Ètò Nípa Ìsọfúnni Rẹ
    • JW.ORG
    • Wọlé
    Fi Ráńṣẹ́