ÀKÁ ÌWÉ ORÍ ÍNTÁNẸ́Ẹ̀TÌ ti Watchtower
ÀKÁ ÌWÉ ORÍ ÍŃTÁNẸ́Ẹ̀TÌ
ti Watchtower
Yorùbá
ọ́
  • ẹ
  • ọ
  • ṣ
  • ń
  • ẹ́
  • ẹ̀
  • ọ́
  • ọ̀
  • BÍBÉLÌ
  • ÌTẸ̀JÁDE
  • ÌPÀDÉ
  • mwb23 November ojú ìwé 8
  • “Ṣé Èèyàn Wúlò fún Ọlọ́run?”

Kò sí fídíò kankan ní apá yìí.

Má bínú, fídíò yìí kò jáde.

  • “Ṣé Èèyàn Wúlò fún Ọlọ́run?”
  • Ìgbésí Ayé àti Iṣẹ́ Òjíṣẹ́ Kristẹni—Ìwé Ìpàdé—2023
  • Àpilẹ̀kọ Míì Tó Jọ ọ́
  • Má Ṣe Sọ̀rọ̀ Bíi Élífásì Tó O Bá Ń Tu Àwọn Èèyàn Nínú
    Ìgbésí Ayé àti Iṣẹ́ Òjíṣẹ́ Kristẹni—Ìwé Ìpàdé—2023
  • Má Ṣe Fàyè Gba Èrò Òdì!
    Ilé Ìṣọ́ Tí Ń Kéde Ìjọba Jehofa—2005
  • Ṣọ́ra Fáwọn Ọ̀rọ̀ Tí Kì Í Ṣòótọ́
    Ìgbésí Ayé àti Iṣẹ́ Òjíṣẹ́ Kristẹni—Ìwé Ìpàdé—2023
  • A San Èrè fún Ìwà Títọ́ Jóòbù
    Ilé Ìṣọ́ Tí Ń Kéde Ìjọba Jehofa—1998
Àwọn Míì
Ìgbésí Ayé àti Iṣẹ́ Òjíṣẹ́ Kristẹni—Ìwé Ìpàdé—2023
mwb23 November ojú ìwé 8

ÀWỌN ÌṢÚRA INÚ Ọ̀RỌ̀ ỌLỌ́RUN

“Ṣé Èèyàn Wúlò fún Ọlọ́run?”

Élífásì sọ pé a ò wúlò lójú Ọlọ́run (Job 22:​1, 2; w05 9/15 26 ¶6–27 ¶2)

Élífásì sọ pé téèyàn bá tiẹ̀ jẹ́ olódodo, kò sí èyí tó kan Ọlọ́run níbẹ̀ (Job 22:3; w95 2/15 27 ¶6)

Tá a bá ṣe ohun tó múnú Jèhófà dùn, àá jẹ́ kó lè fún Sátánì tó ń pẹ̀gàn rẹ̀ lésì (Owe 27:11; w03 4/15 14-15 ¶10-12)

Arábìnrin àgbàlagbà kan ń kan ilẹ̀kùn lẹ́nu iṣẹ́ ìwàásù.

RONÚ LÓRÍ ÌBÉÈRÈ YÌÍ: Báwo ló ṣe rí lára ẹ nígbà tó o mọ̀ pé o wúlò lójú Ọlọ́run Olódùmarè?

    Yorùbá Publications (1987-2025)
    Jáde
    Wọlé
    • Yorùbá
    • Fi Ráńṣẹ́
    • Èyí tí mo fẹ́ràn jù
    • Copyright © 2025 Watch Tower Bible and Tract Society of Pennsylvania
    • Àdéhùn Nípa Lílò
    • Òfin
    • Ètò Nípa Ìsọfúnni Rẹ
    • JW.ORG
    • Wọlé
    Fi Ráńṣẹ́