ÀKÁ ÌWÉ ORÍ ÍNTÁNẸ́Ẹ̀TÌ ti Watchtower
ÀKÁ ÌWÉ ORÍ ÍŃTÁNẸ́Ẹ̀TÌ
ti Watchtower
Yorùbá
ọ́
  • ẹ
  • ọ
  • ṣ
  • ń
  • ẹ́
  • ẹ̀
  • ọ́
  • ọ̀
  • BÍBÉLÌ
  • ÌTẸ̀JÁDE
  • ÌPÀDÉ
  • 1 Kíróníkà 8
  • Bíbélì Mímọ́ ti Ìtumọ̀ Ayé Tuntun

Kò sí fídíò kankan ní apá yìí.

Má bínú, fídíò yìí kò jáde.

Ohun Tó Wà Nínú Ìwé 1 Kíróníkà

      • Àwọn àtọmọdọ́mọ Bẹ́ńjámínì (1-40)

        • Ìlà ìdílé Sọ́ọ̀lù (33-40)

1 Kíróníkà 8:1

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +Jẹ 35:16, 18
  • +1Kr 7:6
  • +Jẹ 46:21

1 Kíróníkà 8:3

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +Jẹ 46:21

1 Kíróníkà 8:6

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +Joṣ 21:8, 17; 1Sa 13:16

1 Kíróníkà 8:8

Àlàyé ìsàlẹ́ ìwé

  • *

    Ní Héb., “pápá.”

  • *

    Tàbí kó jẹ́, “lẹ́yìn tó lé àwọn ìyàwó rẹ̀, Húṣímù àti Báárà kúrò.”

1 Kíróníkà 8:12

Àlàyé ìsàlẹ́ ìwé

  • *

    Tàbí “àwọn ìlú tó yí i ká.”

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +Ne 6:2
  • +Ẹsr 2:1, 33

1 Kíróníkà 8:13

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +Joṣ 19:42, 48; 21:8, 24

1 Kíróníkà 8:29

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +Joṣ 9:15, 17; 21:8, 17; 1Kr 21:29
  • +1Kr 9:35-38

1 Kíróníkà 8:33

Àlàyé ìsàlẹ́ ìwé

  • *

    Wọ́n tún ń pè é ní Íṣí-bóṣétì.

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +1Sa 14:50
  • +1Sa 9:1, 2; 11:15
  • +1Sa 14:45
  • +1Sa 14:49
  • +1Sa 31:2
  • +2Sa 2:8; 1Kr 9:39-44

Atọ́ka

  • Ìwé Ìwádìí

    Ilé Ìṣọ́ (Ẹ̀dà Tó Wà fún Ìkẹ́kọ̀ọ́),

    3/2017, ojú ìwé 32

1 Kíróníkà 8:34

Àlàyé ìsàlẹ́ ìwé

  • *

    Wọ́n tún ń pè é ní Méfíbóṣétì.

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +2Sa 4:4
  • +2Sa 9:12

1 Kíróníkà 8:37

Àlàyé ìsàlẹ́ ìwé

  • *

    Ọ̀rọ̀ yìí ní Hébérù lè túmọ̀ sí ọmọ, ọmọ ọmọ tàbí àtọmọdọ́mọ.

1 Kíróníkà 8:40

Àlàyé ìsàlẹ́ ìwé

  • *

    Ní Héb., “mọ ọrun tẹ̀.”

Àwọn míì

1 Kíró. 8:1Jẹ 35:16, 18
1 Kíró. 8:11Kr 7:6
1 Kíró. 8:1Jẹ 46:21
1 Kíró. 8:3Jẹ 46:21
1 Kíró. 8:6Joṣ 21:8, 17; 1Sa 13:16
1 Kíró. 8:12Ne 6:2
1 Kíró. 8:12Ẹsr 2:1, 33
1 Kíró. 8:13Joṣ 19:42, 48; 21:8, 24
1 Kíró. 8:29Joṣ 9:15, 17; 21:8, 17; 1Kr 21:29
1 Kíró. 8:291Kr 9:35-38
1 Kíró. 8:331Sa 14:50
1 Kíró. 8:331Sa 9:1, 2; 11:15
1 Kíró. 8:331Sa 14:45
1 Kíró. 8:331Sa 14:49
1 Kíró. 8:331Sa 31:2
1 Kíró. 8:332Sa 2:8; 1Kr 9:39-44
1 Kíró. 8:342Sa 4:4
1 Kíró. 8:342Sa 9:12
  • Bíbélì Mímọ́ ti Ìtumọ̀ Ayé Tuntun
  • 1
  • 2
  • 3
  • 4
  • 5
  • 6
  • 7
  • 8
  • 9
  • 10
  • 11
  • 12
  • 13
  • 14
  • 15
  • 16
  • 17
  • 18
  • 19
  • 20
  • 21
  • 22
  • 23
  • 24
  • 25
  • 26
  • 27
  • 28
  • 29
  • 30
  • 31
  • 32
  • 33
  • 34
  • 35
  • 36
  • 37
  • 38
  • 39
  • 40
Bíbélì Mímọ́ ti Ìtumọ̀ Ayé Tuntun
1 Kíróníkà 8:1-40

Kíróníkà Kìíní

8 Bẹ́ńjámínì+ bí Bélà+ àkọ́bí rẹ̀, ọmọ rẹ̀ kejì ni Áṣíbélì,+ ìkẹta ni Áhárà, 2 ìkẹrin ni Nóhà, ìkarùn-ún sì ni Ráfà. 3 Àwọn ọmọ Bélà ni Ádáárì, Gérà,+ Ábíhúdù, 4 Ábíṣúà, Náámánì, Áhóà, 5 Gérà, Ṣéfúfánì àti Húrámù. 6 Àwọn ọmọ Éhúdù nìyí, wọ́n jẹ́ olórí agbo ilé àwọn tó ń gbé Gébà,+ àwọn tí wọ́n kó lọ sí ìgbèkùn ní Mánáhátì, àwọn ni: 7 Náámánì, Áhíjà àti Gérà. Gérà yìí ló kó wọn lọ sí ìgbèkùn, ó sì bí Úúsà àti Áhíhúdù. 8 Ṣáháráímù bí àwọn ọmọ ní ilẹ̀* Móábù lẹ́yìn tí ó lé wọn kúrò. Àwọn ìyàwó rẹ̀ sì ni Húṣímù àti Báárà.* 9 Ìyàwó rẹ̀ Hódéṣì bí àwọn ọmọ fún un, àwọn ni: Jóbábù, Síbíà, Méṣà, Málíkámù, 10 Jéúsì, Sákíà àti Mírímà. Àwọn ni ọmọ rẹ̀, olórí sì ni wọ́n nínú agbo ilé bàbá wọn.

11 Húṣímù bí Ábítúbù àti Élípáálì fún un. 12 Àwọn ọmọ Élípáálì ni Ébérì, Míṣámù àti Ṣémédì (òun ló kọ́ Ónò+ àti Lódì+ pẹ̀lú àwọn àrọko* rẹ̀), 13 Bẹráyà àti Ṣímà. Àwọn ni olórí agbo ilé àwọn tó ń gbé Áíjálónì.+ Àwọn ló lé àwọn tó ń gbé ní Gátì lọ. 14 Áhíò, Ṣáṣákì, Jérémótì, 15 Sebadáyà, Árádì, Édérì, 16 Máíkẹ́lì, Íṣípà, Jóhà, àwọn ọmọ Bẹráyà; 17 àti Sebadáyà, Méṣúlámù, Hísíkì, Hébà, 18 Íṣíméráì, Isiláyà, Jóbábù, àwọn ọmọ Élípáálì; 19 Jákímù, Síkírì, Sábídì, 20 Élíénáì, Sílétáì, Élíélì, 21 Ádáyà, Bẹráyà, Ṣímúrátì, àwọn ọmọ Ṣíméì; 22 Íṣípánì, Ébérì, Élíélì, 23 Ábídónì, Síkírì, Hánánì, 24 Hananáyà, Élámù, Áńtótíjà, 25 Ifidéáyà, Pénúélì, àwọn ọmọ Ṣáṣákì; 26 Ṣámúṣéráì, Ṣẹharáyà, Ataláyà, 27 Jaareṣáyà, Èlíjà, Síkírì, àwọn ọmọ Jéróhámù. 28 Àwọn ni olórí agbo ilé àwọn àtọmọdọ́mọ wọn. Jerúsálẹ́mù ni àwọn olórí yìí ń gbé.

29 Jéélì gbé ní Gíbíónì,+ òun ló sì tẹ ìlú náà dó. Orúkọ ìyàwó rẹ̀ ni Máákà.+ 30 Àkọ́bí rẹ̀ ọkùnrin ni Ábídónì, àwọn tó tẹ̀ lé e ni Súúrì, Kíṣì, Báálì, Nádábù, 31 Gédórì, Áhíò àti Sékà. 32 Míkílótì bí Ṣímẹ́à. Gbogbo wọn gbé nítòsí àwọn arákùnrin wọn ní Jerúsálẹ́mù pẹ̀lú àwọn arákùnrin wọn míì.

33 Nérì+ bí Kíṣì; Kíṣì bí Sọ́ọ̀lù;+ Sọ́ọ̀lù bí Jónátánì,+ Maliki-ṣúà,+ Ábínádábù+ àti Eṣibáálì.*+ 34 Ọmọ Jónátánì ni Meribu-báálì.*+ Meribu-báálì bí Míkà.+ 35 Àwọn ọmọ Míkà ni Pítónì, Mélékì, Táréà àti Áhásì. 36 Áhásì bí Jẹ̀hóádà; Jẹ̀hóádà bí Álémétì, Ásímáfẹ́tì àti Símírì. Símírì bí Mósà. 37 Mósà bí Bínéà, ọmọ* rẹ̀ ni Ráfáhì, ọmọ rẹ̀ ni Éléásà, ọmọ rẹ̀ sì ni Ásélì. 38 Ásélì ní ọmọkùnrin mẹ́fà, orúkọ wọn ni Ásíríkámù, Bókérù, Íṣímáẹ́lì, Ṣearáyà, Ọbadáyà àti Hánánì. Gbogbo wọn ni ọmọ Ásélì. 39 Àwọn ọmọ Éṣékì arákùnrin rẹ̀ ni Úlámù àkọ́bí rẹ̀, ọmọ rẹ̀ kejì ni Jéúṣì, ìkẹta sì ni Élífélétì. 40 Àwọn ọmọ Úlámù jẹ́ jagunjagun tó lákíkanjú tó mọ ọfà lò,* wọn ni ọ̀pọ̀ ọmọ àti ọmọ ọmọ, iye wọn jẹ́ àádọ́jọ (150). Gbogbo àwọn yìí jẹ́ àtọmọdọ́mọ Bẹ́ńjámínì.

Yorùbá Publications (1987-2025)
Jáde
Wọlé
  • Yorùbá
  • Fi Ráńṣẹ́
  • Èyí tí mo fẹ́ràn jù
  • Copyright © 2025 Watch Tower Bible and Tract Society of Pennsylvania
  • Àdéhùn Nípa Lílò
  • Òfin
  • Ètò Nípa Ìsọfúnni Rẹ
  • JW.ORG
  • Wọlé
Fi Ráńṣẹ́