ÀKÁ ÌWÉ ORÍ ÍNTÁNẸ́Ẹ̀TÌ ti Watchtower
ÀKÁ ÌWÉ ORÍ ÍŃTÁNẸ́Ẹ̀TÌ
ti Watchtower
Yorùbá
ọ́
  • ẹ
  • ọ
  • ṣ
  • ń
  • ẹ́
  • ẹ̀
  • ọ́
  • ọ̀
  • BÍBÉLÌ
  • ÌTẸ̀JÁDE
  • ÌPÀDÉ
  • Sáàmù 114
  • Bíbélì Mímọ́ ti Ìtumọ̀ Ayé Tuntun

Kò sí fídíò kankan ní apá yìí.

Má bínú, fídíò yìí kò jáde.

Ohun Tó Wà Nínú Ìwé Sáàmù

      • Ísírẹ́lì bọ́ lọ́wọ́ Íjíbítì

        • Òkun sá lọ (5)

        • Àwọn òkè ń ta pọ́n-ún pọ́n-ún bí àgbò (6)

        • Akọ àpáta di ìsun omi (8)

Sáàmù 114:1

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +Ẹk 12:41

Atọ́ka

  • Ìwé Ìwádìí

    Ilé-Ìṣọ́nà,

    11/15/1992, ojú ìwé 10

Sáàmù 114:2

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +Ẹk 6:7; 19:6; Di 32:9

Atọ́ka

  • Ìwé Ìwádìí

    Ilé-Ìṣọ́nà,

    11/15/1992, ojú ìwé 10

Sáàmù 114:3

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +Ẹk 14:21
  • +Joṣ 3:16

Atọ́ka

  • Ìwé Ìwádìí

    Ilé-Ìṣọ́nà,

    11/15/1992, ojú ìwé 10-11

Sáàmù 114:4

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +Ẹk 19:18; Ond 5:4

Atọ́ka

  • Ìwé Ìwádìí

    Ilé-Ìṣọ́nà,

    11/15/1992, ojú ìwé 10-11

Sáàmù 114:5

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +Ẹk 15:8
  • +Joṣ 4:23

Atọ́ka

  • Ìwé Ìwádìí

    Ilé-Ìṣọ́nà,

    11/15/1992, ojú ìwé 10-11

Sáàmù 114:6

Atọ́ka

  • Ìwé Ìwádìí

    Ilé-Ìṣọ́nà,

    11/15/1992, ojú ìwé 10-11

Sáàmù 114:7

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +1Kr 16:29, 30

Atọ́ka

  • Ìwé Ìwádìí

    Ilé-Ìṣọ́nà,

    11/15/1992, ojú ìwé 11

Sáàmù 114:8

Àlàyé ìsàlẹ́ ìwé

  • *

    Ìyẹn, koríko etí omi.

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +Ẹk 17:6; Nọ 20:11; Di 8:14, 15; Sm 107:35

Atọ́ka

  • Ìwé Ìwádìí

    Ilé-Ìṣọ́nà,

    11/15/1992, ojú ìwé 11

Àwọn míì

Sm 114:1Ẹk 12:41
Sm 114:2Ẹk 6:7; 19:6; Di 32:9
Sm 114:3Ẹk 14:21
Sm 114:3Joṣ 3:16
Sm 114:4Ẹk 19:18; Ond 5:4
Sm 114:5Ẹk 15:8
Sm 114:5Joṣ 4:23
Sm 114:71Kr 16:29, 30
Sm 114:8Ẹk 17:6; Nọ 20:11; Di 8:14, 15; Sm 107:35
  • Bíbélì Mímọ́ ti Ìtumọ̀ Ayé Tuntun
  • 1
  • 2
  • 3
  • 4
  • 5
  • 6
  • 7
  • 8
Bíbélì Mímọ́ ti Ìtumọ̀ Ayé Tuntun
Sáàmù 114:1-8

Sáàmù

114 Nígbà tí Ísírẹ́lì jáde kúrò ní Íjíbítì,+

Tí ilé Jékọ́bù jáde kúrò lọ́dọ̀ àwọn tó ń sọ èdè àjèjì,

 2 Júdà di ibi mímọ́ rẹ̀,

Ísírẹ́lì di ibi tó ń ṣàkóso lé lórí.+

 3 Òkun rí i, ó sì sá lọ;+

Odò Jọ́dánì yíjú pa dà.+

 4 Àwọn òkè ńlá ń ta pọ́n-ún pọ́n-ún kiri bí àgbò,+

Àwọn òkè kéékèèké ń ta bí ọ̀dọ́ àgùntàn.

 5 Kí ló lé ọ léré, ìwọ òkun?+

Kí ló dé tí o fi yíjú pa dà, ìwọ Jọ́dánì?+

 6 Kí ló dé tí ẹ̀yin òkè ńlá fi ń ta pọ́n-ún pọ́n-ún kiri bí àgbò,

Tí ẹ̀yin òkè kéékèèké sì ń ta bí ọ̀dọ́ àgùntàn?

 7 Máa gbọ̀n jìnnìjìnnì nítorí Olúwa, ìwọ ayé,

Nítorí Ọlọ́run Jékọ́bù,+

 8 Ẹni tó ń sọ àpáta di adágún omi tí esùsú* kún inú rẹ̀,

Tó ń sọ akọ àpáta di ìsun omi.+

Yorùbá Publications (1987-2025)
Jáde
Wọlé
  • Yorùbá
  • Fi Ráńṣẹ́
  • Èyí tí mo fẹ́ràn jù
  • Copyright © 2025 Watch Tower Bible and Tract Society of Pennsylvania
  • Àdéhùn Nípa Lílò
  • Òfin
  • Ètò Nípa Ìsọfúnni Rẹ
  • JW.ORG
  • Wọlé
Fi Ráńṣẹ́