ÀKÁ ÌWÉ ORÍ ÍNTÁNẸ́Ẹ̀TÌ ti Watchtower
ÀKÁ ÌWÉ ORÍ ÍŃTÁNẸ́Ẹ̀TÌ
ti Watchtower
Yorùbá
ọ́
  • ẹ
  • ọ
  • ṣ
  • ń
  • ẹ́
  • ẹ̀
  • ọ́
  • ọ̀
  • BÍBÉLÌ
  • ÌTẸ̀JÁDE
  • ÌPÀDÉ
  • Jóṣúà 17
  • Bíbélì Mímọ́ ti Ìtumọ̀ Ayé Tuntun

Kò sí fídíò kankan ní apá yìí.

Má bínú, fídíò yìí kò jáde.

Ohun Tó Wà Nínú Ìwé Jóṣúà

      • Ogún Mánásè ní ìwọ̀ oòrùn (1-13)

      • Àwọn àtọmọdọ́mọ Jósẹ́fù tún gba ilẹ̀ míì (14-18)

Jóṣúà 17:1

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +Nọ 26:55; 33:54; Owe 16:33
  • +Jẹ 41:51; 46:20; 48:17, 18
  • +Di 21:17
  • +Jẹ 50:23; Nọ 26:29; 1Kr 7:14
  • +Di 3:13; Joṣ 13:31

Jóṣúà 17:2

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +Ond 6:11
  • +Nọ 26:29-32

Atọ́ka

  • Ìwé Ìwádìí

    Ilé Ìṣọ́,

    11/15/2007, ojú ìwé 12-13

Jóṣúà 17:3

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +Nọ 26:33

Atọ́ka

  • Ìwé Ìwádìí

    Ilé Ìṣọ́,

    11/15/2007, ojú ìwé 12-13

Jóṣúà 17:4

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +Nọ 27:1, 2; 34:17; Joṣ 14:1
  • +Nọ 27:7, 11
  • +Nọ 36:6, 12

Atọ́ka

  • Ìwé Ìwádìí

    Ilé Ìṣọ́,

    11/15/2007, ojú ìwé 12-13

Jóṣúà 17:5

Àlàyé ìsàlẹ́ ìwé

  • *

    Ìyẹn, apá ìlà oòrùn.

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +Joṣ 13:29

Jóṣúà 17:7

Àlàyé ìsàlẹ́ ìwé

  • *

    Ní Héb., “apá ọ̀tún.”

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +Joṣ 16:5, 6
  • +Joṣ 20:7; 24:1; 1Kr 6:66, 67

Jóṣúà 17:8

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +Joṣ 16:8

Jóṣúà 17:9

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +Joṣ 16:9
  • +Joṣ 16:8

Jóṣúà 17:10

Àlàyé ìsàlẹ́ ìwé

  • *

    Ìyẹn, àwọn ọmọ Mánásè tàbí ilẹ̀ Mánásè.

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +Nọ 34:2, 6

Jóṣúà 17:11

Àlàyé ìsàlẹ́ ìwé

  • *

    Tàbí “ìlú tó yí i ká.”

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +2Ọb 9:27
  • +Joṣ 12:7, 23
  • +1Sa 28:7
  • +Joṣ 12:7, 21

Jóṣúà 17:12

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +Ond 1:27

Jóṣúà 17:13

Àlàyé ìsàlẹ́ ìwé

  • *

    Tàbí “kúrò lórí ilẹ̀ wọn.”

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +Joṣ 16:10; Ond 1:30; 2Kr 8:8
  • +Ẹk 23:33; Nọ 33:55; Di 20:16, 17; Joṣ 23:12, 13; Ond 1:28

Jóṣúà 17:14

Àlàyé ìsàlẹ́ ìwé

  • *

    Ní Héb., “mi.”

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +Nọ 33:54
  • +Jẹ 48:19; Nọ 26:34, 37

Jóṣúà 17:15

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +Ẹk 33:2
  • +Jẹ 15:18-20
  • +Joṣ 24:33

Jóṣúà 17:16

Àlàyé ìsàlẹ́ ìwé

  • *

    Ní Héb., “kẹ̀kẹ́ ogun tí wọ́n fi irin ṣe.”

  • *

    Tàbí “ìlú tó yí i ká.”

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +Di 20:1; Ond 1:19
  • +Joṣ 17:11
  • +Joṣ 19:17, 18; Ond 6:33

Jóṣúà 17:17

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +Joṣ 17:14

Jóṣúà 17:18

Àlàyé ìsàlẹ́ ìwé

  • *

    Ní Héb., “kẹ̀kẹ́ ogun tí wọ́n fi irin ṣe.”

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +Nọ 33:53; Joṣ 20:7; Ond 4:5
  • +Di 20:1; 31:6; Joṣ 13:6; Owe 21:31

Àwọn míì

Jóṣ. 17:1Nọ 26:55; 33:54; Owe 16:33
Jóṣ. 17:1Jẹ 41:51; 46:20; 48:17, 18
Jóṣ. 17:1Di 21:17
Jóṣ. 17:1Jẹ 50:23; Nọ 26:29; 1Kr 7:14
Jóṣ. 17:1Di 3:13; Joṣ 13:31
Jóṣ. 17:2Ond 6:11
Jóṣ. 17:2Nọ 26:29-32
Jóṣ. 17:3Nọ 26:33
Jóṣ. 17:4Nọ 27:1, 2; 34:17; Joṣ 14:1
Jóṣ. 17:4Nọ 27:7, 11
Jóṣ. 17:4Nọ 36:6, 12
Jóṣ. 17:5Joṣ 13:29
Jóṣ. 17:7Joṣ 16:5, 6
Jóṣ. 17:7Joṣ 20:7; 24:1; 1Kr 6:66, 67
Jóṣ. 17:8Joṣ 16:8
Jóṣ. 17:9Joṣ 16:9
Jóṣ. 17:9Joṣ 16:8
Jóṣ. 17:10Nọ 34:2, 6
Jóṣ. 17:112Ọb 9:27
Jóṣ. 17:11Joṣ 12:7, 23
Jóṣ. 17:111Sa 28:7
Jóṣ. 17:11Joṣ 12:7, 21
Jóṣ. 17:12Ond 1:27
Jóṣ. 17:13Joṣ 16:10; Ond 1:30; 2Kr 8:8
Jóṣ. 17:13Ẹk 23:33; Nọ 33:55; Di 20:16, 17; Joṣ 23:12, 13; Ond 1:28
Jóṣ. 17:14Nọ 33:54
Jóṣ. 17:14Jẹ 48:19; Nọ 26:34, 37
Jóṣ. 17:15Ẹk 33:2
Jóṣ. 17:15Jẹ 15:18-20
Jóṣ. 17:15Joṣ 24:33
Jóṣ. 17:16Di 20:1; Ond 1:19
Jóṣ. 17:16Joṣ 17:11
Jóṣ. 17:16Joṣ 19:17, 18; Ond 6:33
Jóṣ. 17:17Joṣ 17:14
Jóṣ. 17:18Nọ 33:53; Joṣ 20:7; Ond 4:5
Jóṣ. 17:18Di 20:1; 31:6; Joṣ 13:6; Owe 21:31
  • Bíbélì Mímọ́ ti Ìtumọ̀ Ayé Tuntun
  • 1
  • 2
  • 3
  • 4
  • 5
  • 6
  • 7
  • 8
  • 9
  • 10
  • 11
  • 12
  • 13
  • 14
  • 15
  • 16
  • 17
  • 18
Bíbélì Mímọ́ ti Ìtumọ̀ Ayé Tuntun
Jóṣúà 17:1-18

Jóṣúà

17 Kèké+ wá mú ẹ̀yà Mánásè,+ torí òun ni àkọ́bí Jósẹ́fù.+ Torí pé ọkùnrin ogun ni Mákírù+ àkọ́bí Mánásè, tó sì jẹ́ bàbá Gílíádì, ó gba Gílíádì àti Báṣánì.+ 2 Kèké sì mú àwọn àtọmọdọ́mọ Mánásè yòókù ní ìdílé-ìdílé, ó mú àwọn ọmọ Abi-ésérì,+ àwọn ọmọ Hélékì, àwọn ọmọ Ásíríélì, àwọn ọmọ Ṣékémù, àwọn ọmọ Héfà àti àwọn ọmọ Ṣẹ́mídà. Àwọn ni àtọmọdọ́mọ Mánásè ọmọ Jósẹ́fù, àwọn ọkùnrin ní ìdílé-ìdílé.+ 3 Àmọ́ Sélóféhádì,+ ọmọ Héfà, ọmọ Gílíádì, ọmọ Mákírù, ọmọ Mánásè kò bímọ ọkùnrin, obìnrin nìkan ló bí, orúkọ àwọn ọmọbìnrin rẹ̀ sì nìyí: Málà, Nóà, Hógílà, Mílíkà àti Tírísà. 4 Wọ́n wá lọ bá àlùfáà Élíásárì,+ Jóṣúà ọmọ Núnì àti àwọn ìjòyè, wọ́n sì sọ pé: “Jèhófà ló pàṣẹ fún Mósè pé kó fún wa ní ogún láàárín àwọn arákùnrin wa.”+ Torí náà, ó fún wọn ní ogún láàárín àwọn arákùnrin bàbá wọn, bí Jèhófà ṣe pa á láṣẹ.+

5 Ilẹ̀ mẹ́wàá ló tún kan Mánásè yàtọ̀ sí ilẹ̀ Gílíádì àti Báṣánì, tó wà ní òdìkejì* Jọ́dánì,+ 6 torí pé àwọn ọmọbìnrin Mánásè náà gba ogún pẹ̀lú àwọn ọmọkùnrin rẹ̀, ilẹ̀ Gílíádì sì wá di ti àwọn àtọmọdọ́mọ Mánásè yòókù.

7 Ààlà Mánásè bẹ̀rẹ̀ láti Áṣérì dé Míkímẹ́tátì,+ tó dojú kọ Ṣékémù,+ ààlà náà sì lọ sí apá gúúsù,* dé ilẹ̀ àwọn tó ń gbé ní Ẹ́ń-Tápúà. 8 Ilẹ̀ Tápúà+ di ti Mánásè, àmọ́ àwọn àtọmọdọ́mọ Éfúrémù ló ni Tápúà tó wà ní ààlà Mánásè. 9 Ààlà náà gba ìsàlẹ̀ lọ sí Àfonífojì Kánà, lápá gúúsù dé àfonífojì náà. Àwọn ìlú Éfúrémù wà láàárín àwọn ìlú Mánásè,+ ààlà Mánásè sì wà ní àríwá àfonífojì náà, ó wá parí sí òkun.+ 10 Éfúrémù ló ni apá gúúsù, Mánásè ló ni apá àríwá, òkun sì ni ààlà rẹ̀,+ wọ́n* dé Áṣérì lápá àríwá, wọ́n sì dé Ísákà lápá ìlà oòrùn.

11 Ní ilẹ̀ Ísákà àti Áṣérì, wọ́n fún Mánásè ní Bẹti-ṣéánì àti àwọn àrọko rẹ̀,* Íbíléámù+ àti àwọn àrọko rẹ̀, àwọn tó ń gbé Dórì+ àti àwọn àrọko rẹ̀, àwọn tó ń gbé Ẹ́ń-dórì+ àti àwọn àrọko rẹ̀, àwọn tó ń gbé Táánákì+ àti àwọn àrọko rẹ̀ àti àwọn tó ń gbé Mẹ́gídò àti àwọn àrọko rẹ̀, mẹ́ta nínú àwọn ibi tó ga.

12 Àmọ́ àwọn àtọmọdọ́mọ Mánásè ò lè gba àwọn ìlú yìí; àwọn ọmọ Kénáánì ṣì ń gbé ilẹ̀ yìí.+ 13 Nígbà tí àwọn ọmọ Ísírẹ́lì di alágbára, wọ́n bẹ̀rẹ̀ sí í fipá kó àwọn ọmọ Kénáánì ṣiṣẹ́ àṣekára,+ àmọ́ wọn ò lé wọn kúrò* pátápátá.+

14 Àwọn àtọmọdọ́mọ Jósẹ́fù sọ fún Jóṣúà pé: “Kí ló dé tí o fi kèké yan ilẹ̀ kan,+ tí o sì fún wa* ní ìpín kan ṣoṣo pé kó jẹ́ ogún wa? Èèyàn púpọ̀ ni wá, torí Jèhófà ti bù kún wa títí di báyìí.”+ 15 Jóṣúà fún wọn lésì pé: “Tó bá jẹ́ pé ẹ pọ̀ tó bẹ́ẹ̀, ẹ lọ sínú igbó, kí ẹ sì ṣán ibì kan fún ara yín níbẹ̀, ní ilẹ̀ àwọn Pérísì+ àti àwọn Réfáímù,+ tó bá jẹ́ pé agbègbè olókè Éfúrémù+ ti kéré jù fún yín.” 16 Àwọn àtọmọdọ́mọ Jósẹ́fù wá sọ pé: “Agbègbè olókè náà ò lè gbà wá, gbogbo àwọn ọmọ Kénáánì tó sì ń gbé ní ilẹ̀ àfonífojì ní àwọn kẹ̀kẹ́ ogun+ tó ní dòjé irin,* ìyẹn àwọn tó wà ní Bẹti-ṣéánì+ àti àwọn àrọko rẹ̀* àti àwọn tó wà ní Àfonífojì Jésírẹ́lì.”+ 17 Jóṣúà wá sọ fún ilé Jósẹ́fù, ó sọ fún Éfúrémù àti Mánásè pé: “Èèyàn púpọ̀ ni yín, ẹ sì lágbára gan-an. Kì í ṣe ilẹ̀ kan péré la máa fi kèké pín fún yín,+ 18 àmọ́ agbègbè olókè náà tún máa di tiyín.+ Bó tiẹ̀ jẹ́ pé igbó ni, ẹ máa ṣán an, ibẹ̀ ló sì máa jẹ́ ìkángun ilẹ̀ yín. Torí ẹ máa lé àwọn ọmọ Kénáánì kúrò níbẹ̀, bó tiẹ̀ jẹ́ pé wọ́n lágbára, wọ́n sì ní àwọn kẹ̀kẹ́ ogun tó ní dòjé irin.”*+

Yorùbá Publications (1987-2025)
Jáde
Wọlé
  • Yorùbá
  • Fi Ráńṣẹ́
  • Èyí tí mo fẹ́ràn jù
  • Copyright © 2025 Watch Tower Bible and Tract Society of Pennsylvania
  • Àdéhùn Nípa Lílò
  • Òfin
  • Ètò Nípa Ìsọfúnni Rẹ
  • JW.ORG
  • Wọlé
Fi Ráńṣẹ́