ÀKÁ ÌWÉ ORÍ ÍNTÁNẸ́Ẹ̀TÌ ti Watchtower
ÀKÁ ÌWÉ ORÍ ÍŃTÁNẸ́Ẹ̀TÌ
ti Watchtower
Yorùbá
ọ́
  • ẹ
  • ọ
  • ṣ
  • ń
  • ẹ́
  • ẹ̀
  • ọ́
  • ọ̀
  • BÍBÉLÌ
  • ÌTẸ̀JÁDE
  • ÌPÀDÉ
  • km 1/15 ojú ìwé 2
  • Ìtòlẹ́sẹẹsẹ fún Ọ̀sẹ̀ January 19

Kò sí fídíò kankan ní apá yìí.

Má bínú, fídíò yìí kò jáde.

  • Ìtòlẹ́sẹẹsẹ fún Ọ̀sẹ̀ January 19
  • Iṣẹ́ Òjíṣẹ́ Ìjọba Wa—2015
  • Ìsọ̀rí
  • Ọ̀SẸ̀ TÓ BẸ̀RẸ̀ NÍ JANUARY 19
Iṣẹ́ Òjíṣẹ́ Ìjọba Wa—2015
km 1/15 ojú ìwé 2

Ìtòlẹ́sẹẹsẹ fún Ọ̀sẹ̀ January 19

Ọ̀SẸ̀ TÓ BẸ̀RẸ̀ NÍ JANUARY 19

Orin 47 àti Àdúrà

Ìkẹ́kọ̀ọ́ Bíbélì Ìjọ:

cl orí 19 ìpínrọ̀ 1 sí 8 (30 min.)

Ilé Ẹ̀kọ́ Ìjọba Ọlọ́run:

Bíbélì kíkà: Onídàájọ́ 1-4 (8 min.)

No. 1: Onídàájọ́ 3:1-11 (3 min. tàbí kó máà tó bẹ́ẹ̀)

No. 2: Báwo Lo Ṣe Lè Mọ Ọlọ́run?—igw ojú ìwé 4 ìpínrọ̀ 1 sí 4 (5 min.)

No. 3: Báwo Ni Ẹ̀mí Ṣe Ń Pa Dà Sọ́dọ̀ Ọlọ́run?—Oníw. 12:7 (5 min.)

Ìpàdé Iṣẹ́ Ìsìn:

ẸṢIN Ọ̀RỌ̀ OṢÙ YÌÍ: Ẹ máa “sìnrú fún Olúwa pẹ̀lú ìrẹ̀lẹ̀ èrò inú títóbi jù lọ.”—Ìṣe 20:19

Orin 77

10 min: Ǹjẹ́ Ò Ń Lo Ìwé Ìwádìí? Ìjíròrò tó dá lórí àwọn ìbéèrè yìí: (1) Báwo ni Ìwé Ìwádìí ṣe lè ràn wá lọ́wọ́ tí a bá ń ka (a) Àwọn Onídàájọ́ 16:1-3 (b) Lúùkù 6:17 àti (d) Róòmù 15:19? (2) Báwo ni Ìwé Ìwádìí ṣe lè ràn wá lọ́wọ́ ká lè lóye àwọn ọ̀rọ̀ wọ̀nyí ní kíkún (a) “ómérì” àti “eéfà (Ẹ́kís. 16:32, 36),” (b) “tálẹ́ńtì (Mát. 25:15),” àti (d) “Ábíbù” àti “Nísàn (Diu. 16:1)”? Ní ìparí ọ̀rọ̀ rẹ, fún gbogbo àwọn ará níṣìírí pé kí wọ́n máa lo ìwé yìí dáadáa.

10 min: Ó Gba Pé Ká Máa Ní Sùúrù Ká Sì Lo Ìdánúṣe Bá A Ṣe Ń Sìnrú fún Olúwa. Ìjíròrò tá a gbé ka Ìwé Ọdọọdún 2014, ojú ìwé 59, ìpínrọ̀ 1 sí ojú ìwé 62, ìpínrọ̀ 1 àti ojú ìwé 67, ìpínrọ̀ 2. Ní kí àwọn ará sọ ẹ̀kọ́ tí wọ́n rí kọ́.

10 min: “Máa Tẹ̀ Síwájú Gẹ́gẹ́ Bí Òjíṣẹ́.” Ìbéèrè àti ìdáhùn.

Orin 20 àti Àdúrà

    Yorùbá Publications (1987-2025)
    Jáde
    Wọlé
    • Yorùbá
    • Fi Ráńṣẹ́
    • Èyí tí mo fẹ́ràn jù
    • Copyright © 2025 Watch Tower Bible and Tract Society of Pennsylvania
    • Àdéhùn Nípa Lílò
    • Òfin
    • Ètò Nípa Ìsọfúnni Rẹ
    • JW.ORG
    • Wọlé
    Fi Ráńṣẹ́