ÀKÁ ÌWÉ ORÍ ÍNTÁNẸ́Ẹ̀TÌ ti Watchtower
ÀKÁ ÌWÉ ORÍ ÍŃTÁNẸ́Ẹ̀TÌ
ti Watchtower
Yorùbá
ọ́
  • ẹ
  • ọ
  • ṣ
  • ń
  • ẹ́
  • ẹ̀
  • ọ́
  • ọ̀
  • BÍBÉLÌ
  • ÌTẸ̀JÁDE
  • ÌPÀDÉ
  • mwb17 March ojú ìwé 4
  • Tá A Bá Tẹ̀lé Ìtọ́sọ́nà Jèhófà Nìkan La Máa Ṣàṣeyọrí

Kò sí fídíò kankan ní apá yìí.

Má bínú, fídíò yìí kò jáde.

  • Tá A Bá Tẹ̀lé Ìtọ́sọ́nà Jèhófà Nìkan La Máa Ṣàṣeyọrí
  • Ìgbésí Ayé àti Iṣẹ́ Òjíṣẹ́ Àwa Kristẹni​—Ìwé Ìpàdé (2017)
  • Àpilẹ̀kọ Míì Tó Jọ ọ́
  • Ohun Tó Wà Nínú Ìwé Yìí
    Jí!—2022
  • ‘Àwọn Olùṣọ́ Àgùntàn Ní Ìbámu Pẹ̀lú Ọkàn-àyà Mi’
    Ọ̀rọ̀ Tí Ọlọ́run Bá Wa Sọ Nípasẹ̀ Jeremáyà
  • Àwọn Olùṣọ́ Àgùntàn Tí Wọ́n Jẹ́ “Àpẹẹrẹ Fún Agbo”
    Ilé Ìṣọ́ Tí Ń Kéde Ìjọba Jehofa—2006
  • “Mo Wà Pẹ̀lú Rẹ Láti Dá Ọ Nídè”
    Ìgbésí Ayé àti Iṣẹ́ Òjíṣẹ́ Àwa Kristẹni​—Ìwé Ìpàdé (2017)
Àwọn Míì
Ìgbésí Ayé àti Iṣẹ́ Òjíṣẹ́ Àwa Kristẹni​—Ìwé Ìpàdé (2017)
mwb17 March ojú ìwé 4

ÀWỌN ÌṢÚRA INÚ Ọ̀RỌ̀ ỌLỌ́RUN | JEREMÁYÀ 8-11

Tá A Bá N Tẹ̀ Lé Ìtọ́sọ́nà Jèhófà Nìkan La Máa Ṣàṣeyọrí

Àwa èèyàn kò lágbára, a ò sì láṣẹ láti darí ara wa

10:​21-23

  • Àwọn ọmọ Ísírẹ́lì tú ká, torí pé àwọn aṣáájú wọn kò wádìí ọ̀rọ̀ lọ́dọ̀ Jèhófà

    Àwọn aṣáájú nílẹ̀ Ísírẹ́lì ń wádìí ọ̀rọ̀ lọ́wọ́ ọlọ́run èké; ilú Jerúsálẹ́mù pa run
  • Àwọn tó ń tẹ̀lé ìtọ́sọ́nà Jèhófà ń ní àláàfíà, ayọ̀, wọ́n sì máa ń ṣàṣeyọrí

    Ọkùnrin kan nílẹ̀ Ísírẹ́lì ń ka òfin Ọlọ́run, òun àti ìdílé rẹ̀ sì wà níṣọkàn, wọ́n láyọ̀, wọ́n sì lásììkí
    Yorùbá Publications (1987-2025)
    Jáde
    Wọlé
    • Yorùbá
    • Fi Ráńṣẹ́
    • Èyí tí mo fẹ́ràn jù
    • Copyright © 2025 Watch Tower Bible and Tract Society of Pennsylvania
    • Àdéhùn Nípa Lílò
    • Òfin
    • Ètò Nípa Ìsọfúnni Rẹ
    • JW.ORG
    • Wọlé
    Fi Ráńṣẹ́