ÀKÁ ÌWÉ ORÍ ÍNTÁNẸ́Ẹ̀TÌ ti Watchtower
ÀKÁ ÌWÉ ORÍ ÍŃTÁNẸ́Ẹ̀TÌ
ti Watchtower
Yorùbá
ọ́
  • ẹ
  • ọ
  • ṣ
  • ń
  • ẹ́
  • ẹ̀
  • ọ́
  • ọ̀
  • BÍBÉLÌ
  • ÌTẸ̀JÁDE
  • ÌPÀDÉ
  • mwb20 August ojú ìwé 8
  • Jẹ́ Kí Ẹ̀mí Jọ Ẹ́ Lójú Bíi Ti Jèhófà

Kò sí fídíò kankan ní apá yìí.

Má bínú, fídíò yìí kò jáde.

  • Jẹ́ Kí Ẹ̀mí Jọ Ẹ́ Lójú Bíi Ti Jèhófà
  • Ìgbésí Ayé àti Iṣẹ́ Òjíṣẹ́ Kristẹni—Ìwé Ìpàdé—2020
  • Àpilẹ̀kọ Míì Tó Jọ ọ́
  • “Ìdáǹdè Yín Ń Sún Mọ́lé”
    Ìgbésí Ayé àti Iṣẹ́ Òjíṣẹ́ Kristẹni—Ìwé Ìpàdé—2018
  • “Ọlọ́run Dán Ábúráhámù Wò”
    Ìgbésí Ayé àti Iṣẹ́ Òjíṣẹ́ Kristẹni—Ìwé Ìpàdé—2020
  • Máa Bọ̀wọ̀ Fáwọn Èèyàn
    Ilé Ìṣọ́ Tí Ń Kéde Ìjọba Jehofa (Tó Wà fún Ìkẹ́kọ̀ọ́)—2025
  • O Lè Mú Kí Ayọ̀ Túbọ̀ Wà Nínú Ìdílé Rẹ
    Ìgbésí Ayé àti Iṣẹ́ Òjíṣẹ́ Kristẹni—Ìwé Ìpàdé—2023
Àwọn Míì
Ìgbésí Ayé àti Iṣẹ́ Òjíṣẹ́ Kristẹni—Ìwé Ìpàdé—2020
mwb20 August ojú ìwé 8
Àwòrán: 1. Ọ̀dọ́kùnrin kan ń bá àgbàlagbà kan gbé ẹrù ẹ̀ lọ sókè. 2. Arábìnrin kan ń wàásù fún obìnrin kan nídìí omi ẹ̀rọ.

ÀWỌN ÌṢÚRA INÚ Ọ̀RỌ̀ ỌLỌ́RUN | Ẹ́KÍSÓDÙ 21-22

Jẹ́ Kí Ẹ̀mí Jọ Ẹ́ Lójú Bíi Ti Jèhófà

21:20, 22, 23, 28, 29

Ẹ̀mí ṣeyebíye gan-an lójú Jèhófà. Báwo làwa náà ṣe lè fi hàn pé ẹ̀mí jọ wá lójú?

  • Nífẹ̀ẹ́ àwọn èèyàn látọkànwá, kó o sì máa bọ̀wọ̀ fún wọn.​—Mt 22:39; 1Jo 3:15

  • Fi kún ìtara ẹ lẹ́nu iṣẹ́ ìwàásù kó lè hàn pé o nífẹ̀ẹ́ àwọn èèyàn lóòótọ́.​—1Kọ 9:​22, 23; 2Pe 3:9

  • Fi hàn pé ọ̀rọ̀ ààbò jẹ ẹ́ lógún.​—Owe 22:3

Tí ẹ̀mí bá jọ wá lójú, báwo nìyẹn ò ṣe ní jẹ́ ká jẹ̀bi ẹ̀jẹ̀?

Arákùnrin kan ń yán bó ṣe ń wakọ̀ lọ lálẹ́.
    Yorùbá Publications (1987-2025)
    Jáde
    Wọlé
    • Yorùbá
    • Fi Ráńṣẹ́
    • Èyí tí mo fẹ́ràn jù
    • Copyright © 2025 Watch Tower Bible and Tract Society of Pennsylvania
    • Àdéhùn Nípa Lílò
    • Òfin
    • Ètò Nípa Ìsọfúnni Rẹ
    • JW.ORG
    • Wọlé
    Fi Ráńṣẹ́