ÀKÁ ÌWÉ ORÍ ÍNTÁNẸ́Ẹ̀TÌ ti Watchtower
ÀKÁ ÌWÉ ORÍ ÍŃTÁNẸ́Ẹ̀TÌ
ti Watchtower
Yorùbá
ọ́
  • ẹ
  • ọ
  • ṣ
  • ń
  • ẹ́
  • ẹ̀
  • ọ́
  • ọ̀
  • BÍBÉLÌ
  • ÌTẸ̀JÁDE
  • ÌPÀDÉ
  • mwb22 January ojú ìwé 15
  • Sọ́ọ̀lù Nírẹ̀lẹ̀, Ó Sì Mọ̀wọ̀n Ara Ẹ̀ Níbẹ̀rẹ̀

Kò sí fídíò kankan ní apá yìí.

Má bínú, fídíò yìí kò jáde.

  • Sọ́ọ̀lù Nírẹ̀lẹ̀, Ó Sì Mọ̀wọ̀n Ara Ẹ̀ Níbẹ̀rẹ̀
  • Ìgbésí Ayé àti Iṣẹ́ Òjíṣẹ́ Kristẹni—Ìwé Ìpàdé—2022
  • Àpilẹ̀kọ Míì Tó Jọ ọ́
  • Téèyàn Bá Kọjá Àyè Ẹ̀, Ó Máa Kan Àbùkù
    Ìgbésí Ayé àti Iṣẹ́ Òjíṣẹ́ Kristẹni—Ìwé Ìpàdé—2022
  • ‘Ìgbọràn Sàn Ju Ẹbọ Lọ’
    Ilé Ìṣọ́ Tí Ń Kéde Ìjọba Jehofa—2011
  • Ìgbọràn Sàn Ju Ẹbọ Lọ
    Ìgbésí Ayé àti Iṣẹ́ Òjíṣẹ́ Kristẹni—Ìwé Ìpàdé—2022
  • Jésù Yan Sọ́ọ̀lù
    Àwọn Ẹ̀kọ́ Tó O Lè Kọ́ Látinú Bíbélì
Àwọn Míì
Ìgbésí Ayé àti Iṣẹ́ Òjíṣẹ́ Kristẹni—Ìwé Ìpàdé—2022
mwb22 January ojú ìwé 15

ÀWỌN ÌṢÚRA INÚ Ọ̀RỌ̀ ỌLỌ́RUN

Sọ́ọ̀lù Nírẹ̀lẹ̀, Ó sì Mọ̀wọ̀n Ara Ẹ̀ Níbẹ̀rẹ̀

Sọ́ọ̀lù mọ̀wọ̀n ara ẹ̀, kò sì kọ́kọ́ gbà nígbà tí wọ́n fẹ́ fi jọba (1Sa 9:21; 10:20-22; w20.08 10 ¶11)

Sọ́ọ̀lù ò bínú nígbà táwọn kan pẹ̀gàn ẹ̀ (1Sa 10:27; 11:12, 13; w14 3/15 9 ¶8)

Sọ́ọ̀lù jẹ́ kí ẹ̀mí Jèhófà darí òun (1Sa 11:5-7; w95 12/15 10 ¶1)

Alàgbà kan ń ka ẹsẹ Bíbélì kan fún arábìnrin kan tó fẹ́ ṣègbéyàwó.

Tá a bá nírẹ̀lẹ̀, a máa gbà pé ẹ̀bùn látọ̀dọ̀ Jèhófà ni àǹfààní iṣẹ́ ìsìn tàbí ẹ̀bùn àbínibí èyíkéyìí tá a ní. (Ro 12:3, 16; 1Kọ 4:7) Bákan náà, tá a bá lẹ́mìí ìrẹ̀lẹ̀, àá jẹ́ kí Jèhófà máa darí wa.

    Yorùbá Publications (1987-2025)
    Jáde
    Wọlé
    • Yorùbá
    • Fi Ráńṣẹ́
    • Èyí tí mo fẹ́ràn jù
    • Copyright © 2025 Watch Tower Bible and Tract Society of Pennsylvania
    • Àdéhùn Nípa Lílò
    • Òfin
    • Ètò Nípa Ìsọfúnni Rẹ
    • JW.ORG
    • Wọlé
    Fi Ráńṣẹ́