ÀKÁ ÌWÉ ORÍ ÍNTÁNẸ́Ẹ̀TÌ ti Watchtower
ÀKÁ ÌWÉ ORÍ ÍŃTÁNẸ́Ẹ̀TÌ
ti Watchtower
Yorùbá
ọ́
  • ẹ
  • ọ
  • ṣ
  • ń
  • ẹ́
  • ẹ̀
  • ọ́
  • ọ̀
  • BÍBÉLÌ
  • ÌTẸ̀JÁDE
  • ÌPÀDÉ
  • Ẹ́kísódù 6
  • Bíbélì Mímọ́ ti Ìtumọ̀ Ayé Tuntun

Kò sí fídíò kankan ní apá yìí.

Má bínú, fídíò yìí kò jáde.

Ohun Tó Wà Nínú Ìwé Ẹ́kísódù

      • Ọlọ́run tún ṣèlérí òmìnira ((1-13)

        • Wọn ò mọ orúkọ Jèhófà délẹ̀délẹ̀ (2, 3)

      • Ìlà ìdílé Mósè àti Áárónì (14-27)

      • Mósè tún máa lọ sọ́dọ̀ Fáráò (28-30)

Ẹ́kísódù 6:1

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +Ẹk 14:13
  • +Ẹk 9:3; 11:1; 12:29, 31

Ẹ́kísódù 6:3

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +Jẹ 17:1; 35:10, 11
  • +Sm 83:18; Lk 11:2; Jo 12:28; Iṣe 15:14; Ifi 15:3
  • +Jẹ 12:8; 28:16; Jer 32:20

Atọ́ka

  • Ìwé Ìwádìí

    Àwọn Ìtẹ̀jáde Tá A Tọ́ka sí Nínú Ìwé Ìpàdé, 7/2020, ojú ìwé 1-2

    Ilé Ìṣọ́,

    3/15/2004, ojú ìwé 25

Ẹ́kísódù 6:4

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +Jẹ 15:18; 28:4

Ẹ́kísódù 6:5

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +Jẹ 17:1, 7; Ẹk 2:24

Ẹ́kísódù 6:6

Àlàyé ìsàlẹ́ ìwé

  • *

    Tàbí “ọwọ́ agbára mi.”

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +Di 4:20
  • +Di 26:8; 1Kr 17:21; Iṣe 13:17

Atọ́ka

  • Ìwé Ìwádìí

    Ilé Ìṣọ́,

    10/15/2012, ojú ìwé 24

Ẹ́kísódù 6:7

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +Ẹk 29:45; Di 7:6; 2Sa 7:24; Sm 33:12

Ẹ́kísódù 6:8

Àlàyé ìsàlẹ́ ìwé

  • *

    Ní Héb., “mo gbé ọwọ́ mi sókè nípa rẹ̀.”

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +Jẹ 15:18; 26:3; 35:12; Ẹk 32:13
  • +Ẹk 20:2; Ais 42:8

Atọ́ka

  • Ìwé Ìwádìí

    Ilé Ìṣọ́,

    10/15/2012, ojú ìwé 24

Ẹ́kísódù 6:9

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +Ẹk 5:21

Ẹ́kísódù 6:12

Àlàyé ìsàlẹ́ ìwé

  • *

    Ní Héb., “mi ò dá ètè mi bí ẹni dá adọ̀dọ́.”

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +Ẹk 5:21; 6:9
  • +Ẹk 4:10; Iṣe 7:22

Atọ́ka

  • Ìwé Ìwádìí

    Ilé Ìṣọ́,

    12/15/2015, ojú ìwé 15

Ẹ́kísódù 6:14

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +Jẹ 49:3
  • +Jẹ 46:9

Ẹ́kísódù 6:15

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +1Kr 4:24

Ẹ́kísódù 6:16

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +Jẹ 29:34
  • +Jẹ 46:11; Nọ 26:57

Ẹ́kísódù 6:17

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +Nọ 3:18

Ẹ́kísódù 6:18

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +Nọ 3:19

Ẹ́kísódù 6:19

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +Nọ 3:20

Ẹ́kísódù 6:20

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +Ẹk 2:1; Nọ 26:59
  • +1Kr 23:13

Ẹ́kísódù 6:21

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +Nọ 16:1, 32; 26:10

Ẹ́kísódù 6:22

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +Le 10:4; Nọ 3:30

Ẹ́kísódù 6:23

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +Rut 4:19-21; Mt 1:4
  • +Nọ 3:2

Ẹ́kísódù 6:24

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +Nọ 26:10, 11
  • +Nọ 26:58; 1Kr 9:19

Ẹ́kísódù 6:25

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +Nọ 3:32
  • +Nọ 25:7; 31:6; Joṣ 22:31; Ond 20:28
  • +Ẹk 6:19

Ẹ́kísódù 6:26

Àlàyé ìsàlẹ́ ìwé

  • *

    Ní Héb., “ẹgbẹ́ ọmọ ogun kọ̀ọ̀kan.”

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +Ẹk 7:2, 4; 12:41; Iṣe 7:35

Ẹ́kísódù 6:27

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +Sm 77:20

Ẹ́kísódù 6:30

Àlàyé ìsàlẹ́ ìwé

  • *

    Ní Héb., “Mi ò dá ètè mi bí ẹni dá adọ̀dọ́.”

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +Ẹk 4:10; 6:12

Àwọn míì

Ẹ́kís. 6:1Ẹk 14:13
Ẹ́kís. 6:1Ẹk 9:3; 11:1; 12:29, 31
Ẹ́kís. 6:3Jẹ 17:1; 35:10, 11
Ẹ́kís. 6:3Sm 83:18; Lk 11:2; Jo 12:28; Iṣe 15:14; Ifi 15:3
Ẹ́kís. 6:3Jẹ 12:8; 28:16; Jer 32:20
Ẹ́kís. 6:4Jẹ 15:18; 28:4
Ẹ́kís. 6:5Jẹ 17:1, 7; Ẹk 2:24
Ẹ́kís. 6:6Di 4:20
Ẹ́kís. 6:6Di 26:8; 1Kr 17:21; Iṣe 13:17
Ẹ́kís. 6:7Ẹk 29:45; Di 7:6; 2Sa 7:24; Sm 33:12
Ẹ́kís. 6:8Jẹ 15:18; 26:3; 35:12; Ẹk 32:13
Ẹ́kís. 6:8Ẹk 20:2; Ais 42:8
Ẹ́kís. 6:9Ẹk 5:21
Ẹ́kís. 6:12Ẹk 5:21; 6:9
Ẹ́kís. 6:12Ẹk 4:10; Iṣe 7:22
Ẹ́kís. 6:14Jẹ 49:3
Ẹ́kís. 6:14Jẹ 46:9
Ẹ́kís. 6:151Kr 4:24
Ẹ́kís. 6:16Jẹ 29:34
Ẹ́kís. 6:16Jẹ 46:11; Nọ 26:57
Ẹ́kís. 6:17Nọ 3:18
Ẹ́kís. 6:18Nọ 3:19
Ẹ́kís. 6:19Nọ 3:20
Ẹ́kís. 6:20Ẹk 2:1; Nọ 26:59
Ẹ́kís. 6:201Kr 23:13
Ẹ́kís. 6:21Nọ 16:1, 32; 26:10
Ẹ́kís. 6:22Le 10:4; Nọ 3:30
Ẹ́kís. 6:23Rut 4:19-21; Mt 1:4
Ẹ́kís. 6:23Nọ 3:2
Ẹ́kís. 6:24Nọ 26:10, 11
Ẹ́kís. 6:24Nọ 26:58; 1Kr 9:19
Ẹ́kís. 6:25Nọ 3:32
Ẹ́kís. 6:25Nọ 25:7; 31:6; Joṣ 22:31; Ond 20:28
Ẹ́kís. 6:25Ẹk 6:19
Ẹ́kís. 6:26Ẹk 7:2, 4; 12:41; Iṣe 7:35
Ẹ́kís. 6:27Sm 77:20
Ẹ́kís. 6:30Ẹk 4:10; 6:12
  • Bíbélì Mímọ́ ti Ìtumọ̀ Ayé Tuntun
  • 1
  • 2
  • 3
  • 4
  • 5
  • 6
  • 7
  • 8
  • 9
  • 10
  • 11
  • 12
  • 13
  • 14
  • 15
  • 16
  • 17
  • 18
  • 19
  • 20
  • 21
  • 22
  • 23
  • 24
  • 25
  • 26
  • 27
  • 28
  • 29
  • 30
Bíbélì Mímọ́ ti Ìtumọ̀ Ayé Tuntun
Ẹ́kísódù 6:1-30

Ẹ́kísódù

6 Jèhófà wá sọ fún Mósè pé: “Ní báyìí, wàá rí ohun tí màá ṣe sí Fáráò.+ Ọwọ́ agbára ló máa mú kó fi wọ́n sílẹ̀, ọwọ́ agbára ló sì máa mú kó lé wọn kúrò ní ilẹ̀ rẹ̀.”+

2 Ọlọ́run wá sọ fún Mósè pé: “Èmi ni Jèhófà. 3 Mo ti máa ń fara han Ábúráhámù, Ísákì àti Jékọ́bù pé èmi ni Ọlọ́run Olódùmarè,+ àmọ́ ní ti orúkọ mi Jèhófà,+ mi ò jẹ́ kí wọ́n fi mọ̀ mí.+ 4 Mo tún bá wọn dá májẹ̀mú pé màá fún wọn ní ilẹ̀ Kénáánì, ilẹ̀ tí wọ́n gbé bí àjèjì.+ 5 Èmi fúnra mi ti gbọ́ bí àwọn ọmọ Ísírẹ́lì ṣe ń kérora, àwọn tí àwọn ará Íjíbítì fi ń ṣẹrú, mo sì rántí májẹ̀mú mi.+

6 “Torí náà, sọ fún àwọn ọmọ Ísírẹ́lì pé: ‘Èmi ni Jèhófà, màá mú yín kúrò lábẹ́ àjàgà àwọn ará Íjíbítì, màá sì gbà yín sílẹ̀ lóko ẹrú.+ Màá fi apá mi tí mo nà jáde* àti àwọn ìdájọ́ tó rinlẹ̀ gbà yín pa dà.+ 7 Màá mú yín bí èèyàn mi, màá sì di Ọlọ́run yín.+ Ó dájú pé ẹ ó mọ̀ pé èmi ni Jèhófà Ọlọ́run yín tó mú yín kúrò lábẹ́ àjàgà àwọn ará Íjíbítì. 8 Màá mú yín wá sí ilẹ̀ tí mo búra* pé màá fún Ábúráhámù, Ísákì àti Jékọ́bù; màá sì mú kó di ohun ìní yín.+ Èmi ni Jèhófà.’”+

9 Nígbà tó yá, Mósè jíṣẹ́ yìí fún àwọn ọmọ Ísírẹ́lì, àmọ́ wọn ò fetí sí Mósè torí wọ́n ti rẹ̀wẹ̀sì àti pé ìyà ń jẹ wọ́n gan-an lóko ẹrú.+

10 Jèhófà wá sọ fún Mósè pé: 11 “Wọlé lọ bá Fáráò ọba Íjíbítì, kí o sì sọ fún un pé kó jẹ́ kí àwọn ọmọ Ísírẹ́lì kúrò ní ilẹ̀ rẹ̀.” 12 Àmọ́ Mósè sọ fún Jèhófà pé: “Wò ó! Àwọn ọmọ Ísírẹ́lì ò fetí sí mi;+ ṣé Fáráò ló máa wá fetí sí mi, èmi tí mi ò lè sọ̀rọ̀ dáadáa?”*+ 13 Àmọ́ Jèhófà tún sọ fún Mósè àti Áárónì nípa àṣẹ tí wọ́n máa pa fún àwọn ọmọ Ísírẹ́lì àti Fáráò ọba Íjíbítì, kí wọ́n lè kó àwọn ọmọ Ísírẹ́lì jáde ní ilẹ̀ Íjíbítì.

14 Àwọn olórí agbo ilé àwọn bàbá wọn nìyí: Àwọn ọmọ Rúbẹ́nì, àkọ́bí Ísírẹ́lì+ ni Hánókù, Pálù, Hésírónì àti Kámì.+ Àwọn ni ìdílé Rúbẹ́nì.

15 Àwọn ọmọ Síméónì ni Jémúélì, Jámínì, Óhádì, Jákínì, Sóhárì àti Ṣéọ́lù ọmọ obìnrin ará Kénáánì.+ Àwọn ni ìdílé Síméónì.

16 Orúkọ àwọn ọmọ Léfì+ nìyí, gẹ́gẹ́ bí ìlà ìdílé wọn: Gẹ́ṣónì, Kóhátì àti Mérárì.+ Ọjọ́ ayé Léfì jẹ́ ọdún mẹ́tàdínlógóje (137).

17 Àwọn ọmọ Gẹ́ṣónì ni Líbínì àti Ṣíméì, gẹ́gẹ́ bí ìdílé wọn.+

18 Àwọn ọmọ Kóhátì ni Ámúrámù, Ísárì, Hébúrónì àti Úsíélì.+ Ọjọ́ ayé Kóhátì jẹ́ ọdún mẹ́tàléláàádóje (133).

19 Àwọn ọmọ Mérárì ni Máhílì àti Múṣì.

Ìdílé àwọn ọmọ Léfì nìyí, gẹ́gẹ́ bí ìlà ìdílé wọn.+

20 Ámúrámù wá fi Jókébédì àbúrò bàbá rẹ̀ ṣe aya.+ Jókébédì sì bí Áárónì àti Mósè fún un.+ Ọjọ́ ayé Ámúrámù jẹ́ ọdún mẹ́tàdínlógóje (137).

21 Àwọn ọmọ Ísárì ni Kórà,+ Néfégì àti Síkírì.

22 Àwọn ọmọ Úsíélì ni Míṣáẹ́lì, Élísáfánì+ àti Sítírì.

23 Áárónì wá fi Élíṣébà, ọmọ Ámínádábù, arábìnrin Náṣónì+ ṣe aya. Ó bí Nádábù, Ábíhù, Élíásárì àti Ítámárì+ fún un.

24 Àwọn ọmọ Kórà ni Ásírì, Ẹlikénà àti Ábíásáfù.+ Ìdílé àwọn ọmọ Kórà+ nìyí.

25 Élíásárì+ ọmọ Áárónì fi ọ̀kan nínú àwọn ọmọbìnrin Pútíélì ṣe aya. Ó bí Fíníhásì fún un.+

Àwọn ni olórí agbo ilé bàbá àwọn ọmọ Léfì, gẹ́gẹ́ bí ìdílé wọn.+

26 Áárónì àti Mósè yìí ni Jèhófà sọ fún pé: “Ẹ mú àwọn ọmọ Ísírẹ́lì kúrò ní ilẹ̀ Íjíbítì, ní àwùjọ-àwùjọ.”*+ 27 Àwọn ló bá Fáráò ọba Íjíbítì sọ̀rọ̀, kí wọ́n lè kó àwọn ọmọ Ísírẹ́lì kúrò ní Íjíbítì. Mósè àti Áárónì+ yìí kan náà ni.

28 Ní ọjọ́ tí Jèhófà bá Mósè sọ̀rọ̀ nílẹ̀ Íjíbítì, 29 Jèhófà sọ fún Mósè pé: “Èmi ni Jèhófà. Sọ gbogbo ohun tí mò ń sọ fún ọ fún Fáráò ọba Íjíbítì.” 30 Mósè wá sọ fún Jèhófà pé: “Wò ó! Mi ò lè sọ̀rọ̀ dáadáa,* ṣé Fáráò á wá fetí sí mi?”+

Yorùbá Publications (1987-2025)
Jáde
Wọlé
  • Yorùbá
  • Fi Ráńṣẹ́
  • Èyí tí mo fẹ́ràn jù
  • Copyright © 2025 Watch Tower Bible and Tract Society of Pennsylvania
  • Àdéhùn Nípa Lílò
  • Òfin
  • Ètò Nípa Ìsọfúnni Rẹ
  • JW.ORG
  • Wọlé
Fi Ráńṣẹ́