ÀKÁ ÌWÉ ORÍ ÍNTÁNẸ́Ẹ̀TÌ ti Watchtower
ÀKÁ ÌWÉ ORÍ ÍŃTÁNẸ́Ẹ̀TÌ
ti Watchtower
Yorùbá
ọ́
  • ẹ
  • ọ
  • ṣ
  • ń
  • ẹ́
  • ẹ̀
  • ọ́
  • ọ̀
  • BÍBÉLÌ
  • ÌTẸ̀JÁDE
  • ÌPÀDÉ
  • Sáàmù 141
  • Bíbélì Mímọ́ ti Ìtumọ̀ Ayé Tuntun

Kò sí fídíò kankan ní apá yìí.

Má bínú, fídíò yìí kò jáde.

Ohun Tó Wà Nínú Ìwé Sáàmù

      • Àdúrà ààbò

        • “Kí àdúrà mi dà bíi tùràrí” (2)

        • Ìbáwí olódodo dà bí òróró (5)

        • Àwọn ẹni burúkú já sí àwọ̀n tí àwọn fúnra wọn dẹ (10)

Sáàmù 141:1

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +Sm 31:17
  • +Sm 40:13; 70:5
  • +Sm 39:12

Sáàmù 141:2

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +Ẹk 30:34-36
  • +Lk 1:9, 10; Ifi 5:8; 8:3, 4
  • +Ẹk 29:41

Atọ́ka

  • Ìwé Ìwádìí

    Ilé Ìṣọ́ (Tó Wà fún Ìkẹ́kọ̀ọ́),

    3/2022, ojú ìwé 21

    Ilé Ìṣọ́,

    6/15/2014, ojú ìwé 16

    1/15/1999, ojú ìwé 10

Sáàmù 141:3

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +Owe 13:3; 21:23; Jem 1:26

Sáàmù 141:4

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +1Ọb 8:58; Sm 119:36

Sáàmù 141:5

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +2Sa 12:7, 9; Owe 17:10; Ga 6:1
  • +Owe 6:23; Jem 5:14
  • +Owe 9:8; 19:25; 25:12

Atọ́ka

  • Ìwé Ìwádìí

    Gbádùn Ayé Rẹ Títí Láé!, ẹ̀kọ́ 57

    Ilé Ìṣọ́,

    4/15/2015, ojú ìwé 31

Sáàmù 141:7

Àlàyé ìsàlẹ́ ìwé

  • *

    Tàbí “Ṣìọ́ọ̀lù,” ìyẹn ibojì aráyé. Wo Àlàyé Ọ̀rọ̀.

Sáàmù 141:8

Àlàyé ìsàlẹ́ ìwé

  • *

    Tàbí “tú ọkàn mi jáde.”

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +2Kr 20:12; Sm 25:15

Sáàmù 141:10

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +Ẹst 7:10; Sm 7:14, 15; 9:15; 57:6

Àwọn míì

Sm 141:1Sm 31:17
Sm 141:1Sm 40:13; 70:5
Sm 141:1Sm 39:12
Sm 141:2Ẹk 30:34-36
Sm 141:2Lk 1:9, 10; Ifi 5:8; 8:3, 4
Sm 141:2Ẹk 29:41
Sm 141:3Owe 13:3; 21:23; Jem 1:26
Sm 141:41Ọb 8:58; Sm 119:36
Sm 141:52Sa 12:7, 9; Owe 17:10; Ga 6:1
Sm 141:5Owe 6:23; Jem 5:14
Sm 141:5Owe 9:8; 19:25; 25:12
Sm 141:82Kr 20:12; Sm 25:15
Sm 141:10Ẹst 7:10; Sm 7:14, 15; 9:15; 57:6
  • Bíbélì Mímọ́ ti Ìtumọ̀ Ayé Tuntun
  • 1
  • 2
  • 3
  • 4
  • 5
  • 6
  • 7
  • 8
  • 9
  • 10
Bíbélì Mímọ́ ti Ìtumọ̀ Ayé Tuntun
Sáàmù 141:1-10

Sáàmù

Orin Dáfídì.

141 Jèhófà, mo ké pè ọ́.+

Tètè wá ràn mí lọ́wọ́.+

Fetí sílẹ̀ nígbà tí mo bá pè ọ́. +

2 Kí àdúrà mi dà bíi tùràrí+ tí a ṣètò sílẹ̀ níwájú rẹ,+

Kí ọwọ́ tí mo gbé sókè dà bí ọrẹ ọkà ìrọ̀lẹ́.+

3 Jèhófà, jọ̀wọ́ yan ẹ̀ṣọ́ fún ẹnu mi,

Kí o sì máa ṣọ́ ilẹ̀kùn ètè mi.+

4 Má ṣe jẹ́ kí ọkàn mi fà sí ohun búburú kankan,+

Kí n má bàa lọ́wọ́ sí iṣẹ́ ibi pẹ̀lú àwọn aṣebi;

Kí n má ṣe jẹ oúnjẹ aládùn wọn láé.

5 Tí olódodo bá gbá mi, á jẹ́ pé ó ní ìfẹ́ tí kì í yẹ̀ sí mi;+

Tó bá bá mi wí, á dà bí òróró ní orí mi,+

Tí orí mi kò ní kọ̀ láé.+

Mi ò ní dákẹ́ àdúrà kódà nígbà tí àjálù bá bá wọn.

6 Bí a tilẹ̀ ju àwọn onídàájọ́ wọn sílẹ̀ láti ibi gẹ̀rẹ́gẹ̀rẹ́ àpáta,

Àwọn èèyàn yóò fetí sí ọ̀rọ̀ mi, torí pé ó lárinrin.

7 Bí ìgbà tí ẹnì kan bá ń tú ilẹ̀, tó sì ń tú u ká,

Bẹ́ẹ̀ ni wọ́n tú egungun wa ká ní ẹnu Isà Òkú.*

8 Ojú rẹ ni mò ń wò, Jèhófà Olúwa Ọba Aláṣẹ.+

Ìwọ ni mo fi ṣe ibi ààbò mi.

Má ṣe gba ẹ̀mí mi.*

9 Dáàbò bò mí kí n má bàa kó sí ẹnu pańpẹ́ tí wọ́n dẹ dè mí,

Lọ́wọ́ ìdẹkùn àwọn aṣebi.

10 Àwọn ẹni burúkú lápapọ̀ yóò já sínú àwọ̀n tí àwọn fúnra wọn dẹ,+

Èmi á sì kọjá lọ láìséwu.

Yorùbá Publications (1987-2025)
Jáde
Wọlé
  • Yorùbá
  • Fi Ráńṣẹ́
  • Èyí tí mo fẹ́ràn jù
  • Copyright © 2025 Watch Tower Bible and Tract Society of Pennsylvania
  • Àdéhùn Nípa Lílò
  • Òfin
  • Ètò Nípa Ìsọfúnni Rẹ
  • JW.ORG
  • Wọlé
Fi Ráńṣẹ́