ÀKÁ ÌWÉ ORÍ ÍNTÁNẸ́Ẹ̀TÌ ti Watchtower
ÀKÁ ÌWÉ ORÍ ÍŃTÁNẸ́Ẹ̀TÌ
ti Watchtower
Yorùbá
ọ́
  • ẹ
  • ọ
  • ṣ
  • ń
  • ẹ́
  • ẹ̀
  • ọ́
  • ọ̀
  • BÍBÉLÌ
  • ÌTẸ̀JÁDE
  • ÌPÀDÉ
  • mwb19 May ojú ìwé 4
  • Ẹ̀gún Nínú Ara Pọ́ọ̀lù

Kò sí fídíò kankan ní apá yìí.

Má bínú, fídíò yìí kò jáde.

  • Ẹ̀gún Nínú Ara Pọ́ọ̀lù
  • Ìgbésí Ayé àti Iṣẹ́ Òjíṣẹ́ Kristẹni—Ìwé Ìpàdé—2019
  • Àpilẹ̀kọ Míì Tó Jọ ọ́
  • Wọ́n Fara Da Ẹ̀gún Nínú Ẹran Ara Wọn
    Ilé Ìṣọ́ Tí Ń Kéde Ìjọba Jehofa—2002
  • Fífarada ‘Ẹ̀gún Nínú Ẹran Ara’
    Ilé Ìṣọ́ Tí Ń Kéde Ìjọba Jehofa—2002
  • Àìlera Ẹ̀dá Ènìyàn Ń Fi Hàn Pé Agbára Jèhófà Pọ̀
    Ilé Ìṣọ́ Tí Ń Kéde Ìjọba Jehofa—1997
  • O Ha Ní ‘Ẹ̀gún Kan Nínú Ẹran Ara’ Bí?
    Iṣẹ́ Òjíṣẹ́ Ìjọba Wa—1998
Àwọn Míì
Ìgbésí Ayé àti Iṣẹ́ Òjíṣẹ́ Kristẹni—Ìwé Ìpàdé—2019
mwb19 May ojú ìwé 4

ÀWỌN ÌṢÚRA INÚ Ọ̀RỌ̀ ỌLỌ́RUN | 2 KỌ́RÍŃTÌ 11-13

Ẹ̀gún Nínú Ara Pọ́ọ̀lù

12:7-10

Bíbélì sábà máa ń lo ẹ̀gún lọ́nà ìṣàpẹẹrẹ. Bíbélì lè lò ó láti tọ́ka sí èèyàn tó máa ń fa ìjàǹbá, tó sì máa ń kó ìdààmú báni tàbí nǹkan míì tó lè fa ìṣòro. (Nọ 33:55; Owe 22:5; Isk 28:24) Nígbà tí Pọ́ọ̀lù kọ̀wé nípa “ẹ̀gún” tó wà nínú ara rẹ̀, ó ṣeé ṣe kó máa tọ́ka sí àwọn àpọ́sítélì èké àtàwọn míì tó ń ta kò ó pé ayédèrú àpọ́sítélì ni. Báwo làwọn ẹsẹ Bíbélì tó wà nísàlẹ̀ yìí ṣe jẹ́ ká mọ nǹkan míì tó ṣeé ṣe kó tún jẹ́ “ẹ̀gún” nínú ẹran ara Pọ́ọ̀lù?

  • Àpọ́sítélì Pọ́ọ̀lù fọwọ́ sórí

    Iṣe 23:1-5

  • Ga 4:14, 15

  • Ga 6:11

Kí ni “ẹ̀gún” tó wà nínú ara rẹ?

Báwo lo ṣe lè gbára lé Jèhófà kó lè ràn ẹ́ lọ́wọ́ láti fara dà á?

    Yorùbá Publications (1987-2025)
    Jáde
    Wọlé
    • Yorùbá
    • Fi Ráńṣẹ́
    • Èyí tí mo fẹ́ràn jù
    • Copyright © 2025 Watch Tower Bible and Tract Society of Pennsylvania
    • Àdéhùn Nípa Lílò
    • Òfin
    • Ètò Nípa Ìsọfúnni Rẹ
    • JW.ORG
    • Wọlé
    Fi Ráńṣẹ́