ÀKÁ ÌWÉ ORÍ ÍNTÁNẸ́Ẹ̀TÌ ti Watchtower
ÀKÁ ÌWÉ ORÍ ÍŃTÁNẸ́Ẹ̀TÌ
ti Watchtower
Yorùbá
ọ́
  • ẹ
  • ọ
  • ṣ
  • ń
  • ẹ́
  • ẹ̀
  • ọ́
  • ọ̀
  • BÍBÉLÌ
  • ÌTẸ̀JÁDE
  • ÌPÀDÉ
  • Jóṣúà 13
  • Bíbélì Mímọ́ ti Ìtumọ̀ Ayé Tuntun

Kò sí fídíò kankan ní apá yìí.

Má bínú, fídíò yìí kò jáde.

Ohun Tó Wà Nínú Ìwé Jóṣúà

      • Àwọn ilẹ̀ tí wọn ò tíì gbà (1-7)

      • Wọ́n pín ilẹ̀ tó wà ní ìlà oòrùn Jọ́dánì (8-14)

      • Ogún Rúbẹ́nì (15-23)

      • Ogún Gádì (24-28)

      • Ogún Mánásè ní ìlà oòrùn (29-32)

      • Jèhófà ni ogún àwọn ọmọ Léfì (33)

Jóṣúà 13:1

Àlàyé ìsàlẹ́ ìwé

  • *

    Tàbí “ṣẹ́gun.”

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +Joṣ 23:1; 24:29

Atọ́ka

  • Ìwé Ìwádìí

    Ilé Ìṣọ́,

    12/1/2004, ojú ìwé 11-12

Jóṣúà 13:2

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +Ẹk 23:29, 30
  • +1Sa 27:8

Jóṣúà 13:3

Àlàyé ìsàlẹ́ ìwé

  • *

    Tàbí “láti Ṣíhórì.”

  • *

    Ní Héb., “níwájú.”

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +Jẹ 10:19
  • +Ond 3:1, 3; 1Sa 6:4
  • +Joṣ 15:20, 46
  • +Ond 14:19
  • +2Sa 21:19
  • +1Sa 5:10
  • +Di 2:23

Jóṣúà 13:4

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +Ond 1:31

Jóṣúà 13:5

Àlàyé ìsàlẹ́ ìwé

  • *

    Tàbí “àbáwọlé Hámátì.”

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +1Ọb 5:18
  • +Nọ 34:2, 8

Jóṣúà 13:6

Àlàyé ìsàlẹ́ ìwé

  • *

    Tàbí “mú wọn kúrò lórí ilẹ̀ wọn.”

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +Di 3:25
  • +Joṣ 11:8
  • +Ond 3:1-3
  • +Ẹk 23:30
  • +Nọ 34:17; Joṣ 14:1

Jóṣúà 13:7

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +Nọ 33:54

Jóṣúà 13:8

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +Nọ 32:33; Joṣ 22:4

Jóṣúà 13:9

Àlàyé ìsàlẹ́ ìwé

  • *

    Tàbí “òkè tí orí rẹ̀ rí pẹrẹsẹ.”

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +Di 3:12
  • +Nọ 21:13

Jóṣúà 13:10

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +Nọ 21:23, 24

Jóṣúà 13:11

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +Di 3:14
  • +Joṣ 17:1
  • +1Kr 5:11

Jóṣúà 13:12

Àlàyé ìsàlẹ́ ìwé

  • *

    Tàbí “mú wọn kúrò lórí ilẹ̀ wọn.”

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +Di 3:11
  • +Nọ 21:23, 24, 33-35

Jóṣúà 13:13

Àlàyé ìsàlẹ́ ìwé

  • *

    Tàbí “kúrò lórí ilẹ̀ wọn.”

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +Nọ 33:55; Joṣ 23:12, 13

Jóṣúà 13:14

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +Nọ 18:20; Di 10:9; 12:12
  • +Le 7:33-35; Di 18:1
  • +Nọ 18:24

Jóṣúà 13:17

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +Nọ 21:25, 26
  • +Nọ 32:37, 38

Jóṣúà 13:18

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +Nọ 21:23
  • +Di 2:26
  • +Joṣ 21:8, 37

Jóṣúà 13:19

Àlàyé ìsàlẹ́ ìwé

  • *

    Tàbí “pẹ̀tẹ́lẹ̀.”

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +Nọ 32:37, 38

Jóṣúà 13:20

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +Di 3:16, 17
  • +Nọ 33:48, 49

Jóṣúà 13:21

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +Nọ 21:25
  • +Di 2:30
  • +Nọ 31:7, 8

Jóṣúà 13:22

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +Nọ 22:5; 2Pe 2:15
  • +Nọ 22:7

Jóṣúà 13:25

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +Nọ 32:34, 35
  • +Joṣ 12:2; Ond 11:13
  • +2Sa 11:1

Jóṣúà 13:26

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +Nọ 21:26
  • +Jẹ 32:2; Joṣ 21:8, 38

Jóṣúà 13:27

Àlàyé ìsàlẹ́ ìwé

  • *

    Tàbí “pẹ̀tẹ́lẹ̀.”

  • *

    Ìyẹn, adágún odò Jẹ́nẹ́sárẹ́tì tàbí Òkun Gálílì.

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +Nọ 32:34, 36
  • +Jẹ 33:17
  • +Nọ 21:26
  • +Nọ 34:2, 11; Di 3:16, 17; Jo 6:1

Jóṣúà 13:29

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +Di 3:13

Jóṣúà 13:30

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +1Kr 6:77, 80
  • +Nọ 32:40, 41; Di 3:14

Jóṣúà 13:31

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +Nọ 21:33
  • +Nọ 32:39

Jóṣúà 13:32

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +Nọ 32:33

Jóṣúà 13:33

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +Di 10:9; Joṣ 18:7
  • +Nọ 18:24; 26:62, 63; Di 18:1

Àwọn míì

Jóṣ. 13:1Joṣ 23:1; 24:29
Jóṣ. 13:2Ẹk 23:29, 30
Jóṣ. 13:21Sa 27:8
Jóṣ. 13:3Jẹ 10:19
Jóṣ. 13:3Ond 3:1, 3; 1Sa 6:4
Jóṣ. 13:3Joṣ 15:20, 46
Jóṣ. 13:3Ond 14:19
Jóṣ. 13:32Sa 21:19
Jóṣ. 13:31Sa 5:10
Jóṣ. 13:3Di 2:23
Jóṣ. 13:4Ond 1:31
Jóṣ. 13:51Ọb 5:18
Jóṣ. 13:5Nọ 34:2, 8
Jóṣ. 13:6Di 3:25
Jóṣ. 13:6Joṣ 11:8
Jóṣ. 13:6Ond 3:1-3
Jóṣ. 13:6Ẹk 23:30
Jóṣ. 13:6Nọ 34:17; Joṣ 14:1
Jóṣ. 13:7Nọ 33:54
Jóṣ. 13:8Nọ 32:33; Joṣ 22:4
Jóṣ. 13:9Di 3:12
Jóṣ. 13:9Nọ 21:13
Jóṣ. 13:10Nọ 21:23, 24
Jóṣ. 13:11Di 3:14
Jóṣ. 13:11Joṣ 17:1
Jóṣ. 13:111Kr 5:11
Jóṣ. 13:12Di 3:11
Jóṣ. 13:12Nọ 21:23, 24, 33-35
Jóṣ. 13:13Nọ 33:55; Joṣ 23:12, 13
Jóṣ. 13:14Nọ 18:20; Di 10:9; 12:12
Jóṣ. 13:14Le 7:33-35; Di 18:1
Jóṣ. 13:14Nọ 18:24
Jóṣ. 13:17Nọ 21:25, 26
Jóṣ. 13:17Nọ 32:37, 38
Jóṣ. 13:18Nọ 21:23
Jóṣ. 13:18Di 2:26
Jóṣ. 13:18Joṣ 21:8, 37
Jóṣ. 13:19Nọ 32:37, 38
Jóṣ. 13:20Di 3:16, 17
Jóṣ. 13:20Nọ 33:48, 49
Jóṣ. 13:21Nọ 21:25
Jóṣ. 13:21Di 2:30
Jóṣ. 13:21Nọ 31:7, 8
Jóṣ. 13:22Nọ 22:5; 2Pe 2:15
Jóṣ. 13:22Nọ 22:7
Jóṣ. 13:25Nọ 32:34, 35
Jóṣ. 13:25Joṣ 12:2; Ond 11:13
Jóṣ. 13:252Sa 11:1
Jóṣ. 13:26Nọ 21:26
Jóṣ. 13:26Jẹ 32:2; Joṣ 21:8, 38
Jóṣ. 13:27Nọ 32:34, 36
Jóṣ. 13:27Jẹ 33:17
Jóṣ. 13:27Nọ 21:26
Jóṣ. 13:27Nọ 34:2, 11; Di 3:16, 17; Jo 6:1
Jóṣ. 13:29Di 3:13
Jóṣ. 13:301Kr 6:77, 80
Jóṣ. 13:30Nọ 32:40, 41; Di 3:14
Jóṣ. 13:31Nọ 21:33
Jóṣ. 13:31Nọ 32:39
Jóṣ. 13:32Nọ 32:33
Jóṣ. 13:33Di 10:9; Joṣ 18:7
Jóṣ. 13:33Nọ 18:24; 26:62, 63; Di 18:1
  • Bíbélì Mímọ́ ti Ìtumọ̀ Ayé Tuntun
  • 1
  • 2
  • 3
  • 4
  • 5
  • 6
  • 7
  • 8
  • 9
  • 10
  • 11
  • 12
  • 13
  • 14
  • 15
  • 16
  • 17
  • 18
  • 19
  • 20
  • 21
  • 22
  • 23
  • 24
  • 25
  • 26
  • 27
  • 28
  • 29
  • 30
  • 31
  • 32
  • 33
Bíbélì Mímọ́ ti Ìtumọ̀ Ayé Tuntun
Jóṣúà 13:1-33

Jóṣúà

13 Ní báyìí, Jóṣúà ti darúgbó, ó sì ti lọ́jọ́ lórí.+ Jèhófà sọ fún un pé: “O ti darúgbó, o sì ti lọ́jọ́ lórí; àmọ́ ẹ ò tíì gba* èyí tó pọ̀ jù nínú ilẹ̀ náà. 2 Àwọn ilẹ̀ tó ṣẹ́ kù nìyí:+ gbogbo ilẹ̀ àwọn Filísínì àti ti gbogbo àwọn ará Géṣúrì+ 3 (láti ẹ̀ka odò Náílì* tó wà ní ìlà oòrùn* Íjíbítì títí dé ààlà Ẹ́kírónì lọ sí àríwá, tí wọ́n máa ń pè ní ilẹ̀ àwọn ọmọ Kénáánì)+ pẹ̀lú ilẹ̀ àwọn alákòóso Filísínì márààrún,+ ìyẹn àwọn ará Gásà, àwọn ará Áṣídódì,+ àwọn ará Áṣíkẹ́lónì,+ àwọn ará Gátì+ àti àwọn ará Ẹ́kírónì;+ ilẹ̀ àwọn Áfímù+ 4 lọ sí apá gúúsù; gbogbo ilẹ̀ àwọn ọmọ Kénáánì; Méárà, tó jẹ́ ti àwọn ọmọ Sídónì,+ títí lọ dé Áfékì, dé ààlà àwọn Ámórì; 5 ilẹ̀ àwọn ará Gébálì+ àti gbogbo Lẹ́bánónì lápá ìlà oòrùn, láti Baali-gádì ní ìsàlẹ̀ Òkè Hámónì títí dé Lebo-hámátì;*+ 6 gbogbo àwọn tó ń gbé agbègbè olókè láti Lẹ́bánónì+ lọ dé Misirefoti-máímù;+ àti gbogbo àwọn ọmọ Sídónì.+ Mo máa lé wọn kúrò* níwájú àwọn ọmọ Ísírẹ́lì.+ Kí o ṣáà rí i pé o pín in fún Ísírẹ́lì pé kó jẹ́ ogún wọn, bí mo ṣe pa á láṣẹ fún ọ.+ 7 Kí o pín ilẹ̀ yìí fún ẹ̀yà mẹ́sàn-án àti ààbọ̀ ẹ̀yà Mánásè pé kó jẹ́ ogún wọn.”+

8 Àwọn ọmọ Rúbẹ́nì, àwọn ọmọ Gádì àti ààbọ̀ ẹ̀yà tó kù, wá gba ogún wọn tí Mósè fún wọn lápá ìlà oòrùn Jọ́dánì, bí Mósè ìránṣẹ́ Jèhófà ṣe fún wọn:+ 9 láti Áróérì,+ tó wà létí Àfonífojì Áánónì+ àti ìlú tó wà láàárín àfonífojì náà àti gbogbo ilẹ̀ tó tẹ́jú* ní Médébà títí dé Díbónì; 10 àti gbogbo ìlú Síhónì ọba àwọn Ámórì, tó jọba ní Hẹ́ṣíbónì, títí dé ààlà àwọn ọmọ Ámónì;+ 11 pẹ̀lú Gílíádì àti ilẹ̀ àwọn ará Géṣúrì àti tàwọn ará Máákátì+ àti gbogbo Òkè Hámónì pẹ̀lú gbogbo Báṣánì+ títí lọ dé Sálékà;+ 12 gbogbo ilẹ̀ ọba Ógù ní Báṣánì, tó jọba ní Áṣítárótì àti Édíréì. (Ó jẹ́ ọ̀kan lára àwọn Réfáímù+ tó kẹ́yìn.) Mósè ṣẹ́gun wọn, ó sì lé wọn kúrò.*+ 13 Àmọ́ àwọn ọmọ Ísírẹ́lì kò lé+ àwọn ará Géṣúrì àti àwọn ará Máákátì kúrò,* torí àwọn Géṣúrì àti Máákátì ṣì wà láàárín Ísírẹ́lì títí di òní yìí.

14 Ẹ̀yà àwọn ọmọ Léfì nìkan ni kò pín ogún fún.+ Àwọn ọrẹ àfinásun sí Jèhófà Ọlọ́run Ísírẹ́lì ni ogún wọn,+ bó ṣe ṣèlérí fún wọn.+

15 Mósè pín ogún fún ẹ̀yà àwọn ọmọ Rúbẹ́nì ní ìdílé-ìdílé, 16 ilẹ̀ wọn bẹ̀rẹ̀ láti Áróérì, tó wà létí Àfonífojì Áánónì àti ìlú tó wà láàárín àfonífojì náà pẹ̀lú gbogbo ilẹ̀ tó tẹ́jú lẹ́gbẹ̀ẹ́ Médébà; 17 Hẹ́ṣíbónì àti gbogbo ìlú rẹ̀+ tó wà lórí ilẹ̀ tó tẹ́jú, Díbónì, Bamoti-báálì, Bẹti-baali-méónì,+ 18 Jáhásì,+ Kédémótì,+ Mẹ́fáátì,+ 19 Kiriátáímù, Síbúmà,+ Sereti-ṣáhà lórí òkè tó wà ní àfonífojì,* 20 Bẹti-péórì, gẹ̀rẹ́gẹ̀rẹ́ Písígà,+ Bẹti-jẹ́ṣímótì,+ 21 gbogbo ìlú tó wà lórí ilẹ̀ tó tẹ́jú àti gbogbo ilẹ̀ Síhónì ọba àwọn Ámórì, tó jọba ní Hẹ́ṣíbónì.+ Mósè ṣẹ́gun òun+ àtàwọn ìjòyè Mídíánì, ìyẹn Éfì, Rékémù, Súúrì, Húrì àti Rébà,+ àwọn ọba tó wà lábẹ́ Síhónì, tí wọ́n ń gbé ilẹ̀ náà. 22 Àwọn ọmọ Ísírẹ́lì fi idà pa Báláámù+ ọmọ Béórì, tó jẹ́ woṣẹ́woṣẹ́+ pẹ̀lú àwọn yòókù tí wọ́n pa. 23 Jọ́dánì ni ààlà àwọn ọmọ Rúbẹ́nì; ilẹ̀ yìí sì ni ogún àwọn ọmọ Rúbẹ́nì ní ìdílé-ìdílé, pẹ̀lú àwọn ìlú náà àtàwọn ìgbèríko wọn.

24 Bákan náà, Mósè pín ogún fún ẹ̀yà Gádì, àwọn ọmọ Gádì ní ìdílé-ìdílé, 25 ara ilẹ̀ wọn sì ni Jásérì+ àti gbogbo ìlú tó wà ní Gílíádì pẹ̀lú ìdajì ilẹ̀ àwọn ọmọ Ámónì+ títí dé Áróérì, èyí tó dojú kọ Rábà;+ 26 láti Hẹ́ṣíbónì+ dé Ramati-mísípè àti Bẹ́tónímù àti láti Máhánáímù+ títí dé ààlà Débírì; 27 àti ní àfonífojì,* Bẹti-hárámù, Bẹti-nímírà,+ Súkótù+ àti Sáfónì, èyí tó kù nínú ilẹ̀ Síhónì ọba Hẹ́ṣíbónì,+ tí Jọ́dánì jẹ́ ààlà rẹ̀ láti apá ìsàlẹ̀ Òkun Kínérétì*+ lápá ìlà oòrùn Jọ́dánì. 28 Ogún àwọn ọmọ Gádì nìyí ní ìdílé-ìdílé, pẹ̀lú àwọn ìlú náà àtàwọn ìgbèríko wọn.

29 Yàtọ̀ síyẹn, Mósè pín ogún fún ààbọ̀ ẹ̀yà Mánásè, ìdajì nínú ẹ̀yà Mánásè ní ìdílé-ìdílé.+ 30 Ilẹ̀ wọn bẹ̀rẹ̀ láti Máhánáímù+ tó fi mọ́ gbogbo Báṣánì, gbogbo ilẹ̀ Ógù ọba Báṣánì àti gbogbo abúlé Jáírì+ tí wọ́n pàgọ́ sí ní Báṣánì, ó jẹ́ ọgọ́ta (60) ìlú. 31 Ìdajì Gílíádì pẹ̀lú Áṣítárótì àti Édíréì,+ àwọn ìlú tó wà ní ilẹ̀ ọba Ógù ní Báṣánì, di ti àwọn ọmọ Mákírù,+ ọmọ Mánásè, ìyẹn ìdajì àwọn ọmọ Mákírù ní ìdílé-ìdílé.

32 Èyí ni ogún tí Mósè pín fún wọn ní aṣálẹ̀ tó tẹ́jú ní Móábù ní ìkọjá Jọ́dánì, lápá ìlà oòrùn Jẹ́ríkò.+

33 Àmọ́ Mósè ò fún ẹ̀yà àwọn ọmọ Léfì ní ogún kankan.+ Jèhófà Ọlọ́run Ísírẹ́lì ni ogún wọn, bó ṣe ṣèlérí fún wọn.+

Yorùbá Publications (1987-2025)
Jáde
Wọlé
  • Yorùbá
  • Fi Ráńṣẹ́
  • Èyí tí mo fẹ́ràn jù
  • Copyright © 2025 Watch Tower Bible and Tract Society of Pennsylvania
  • Àdéhùn Nípa Lílò
  • Òfin
  • Ètò Nípa Ìsọfúnni Rẹ
  • JW.ORG
  • Wọlé
Fi Ráńṣẹ́