ÀKÁ ÌWÉ ORÍ ÍNTÁNẸ́Ẹ̀TÌ ti Watchtower
ÀKÁ ÌWÉ ORÍ ÍŃTÁNẸ́Ẹ̀TÌ
ti Watchtower
Yorùbá
ọ́
  • ẹ
  • ọ
  • ṣ
  • ń
  • ẹ́
  • ẹ̀
  • ọ́
  • ọ̀
  • BÍBÉLÌ
  • ÌTẸ̀JÁDE
  • ÌPÀDÉ
  • Jeremáyà 2
  • Bíbélì Mímọ́ ti Ìtumọ̀ Ayé Tuntun

Kò sí fídíò kankan ní apá yìí.

Má bínú, fídíò yìí kò jáde.

Ohun Tó Wà Nínú Ìwé Jeremáyà

      • Ísírẹ́lì fi Jèhófà sílẹ̀ láti lọ jọ́sìn àwọn ọlọ́run míì (1-37)

        • Ísírẹ́lì dà bí àjàrà ilẹ̀ òkèèrè (21)

        • Ẹ̀jẹ̀ ta sí i láṣọ (34)

Jeremáyà 2:2

Àlàyé ìsàlẹ́ ìwé

  • *

    Tàbí “ìfẹ́ tí kì í yẹ̀.”

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +Ho 2:15
  • +Ẹk 24:3
  • +Di 2:7

Jeremáyà 2:3

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +Ẹk 19:6; Di 7:6
  • +Ẹk 17:8, 13

Jeremáyà 2:5

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +Ais 5:4; Mik 6:3
  • +Di 32:21
  • +Sm 115:4, 8

Jeremáyà 2:6

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +Ẹk 14:30
  • +Di 1:1; 32:9, 10
  • +Di 8:14, 15

Atọ́ka

  • Ìwé Ìwádìí

    Ilé Ìṣọ́,

    5/1/2003, ojú ìwé 8

Jeremáyà 2:7

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +Nọ 13:26, 27; Di 6:10, 11; 8:7-9
  • +Le 18:24; Nọ 35:33; Sm 78:58; 106:38; Jer 16:18

Jeremáyà 2:8

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +1Sa 2:12; Ida 4:13
  • +Isk 34:7, 8
  • +1Ọb 18:19; Jer 23:13

Jeremáyà 2:9

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +Isk 20:35; Mik 6:2

Jeremáyà 2:10

Àlàyé ìsàlẹ́ ìwé

  • *

    Tàbí “erékùṣù.”

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +Jẹ 10:2, 4
  • +Jẹ 25:13; Sm 120:5; Jer 49:28

Atọ́ka

  • Ìwé Ìwádìí

    Ilé Ìṣọ́,

    3/15/2007, ojú ìwé 9

Jeremáyà 2:11

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +Sm 106:20

Atọ́ka

  • Ìwé Ìwádìí

    Ilé Ìṣọ́,

    3/15/2007, ojú ìwé 9

Jeremáyà 2:13

Àlàyé ìsàlẹ́ ìwé

  • *

    Tàbí “wa àwọn kòtò omi,” bóyá sínú àpáta.

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +Sm 36:9; Jer 17:13; Ifi 22:1

Atọ́ka

  • Ìwé Ìwádìí

    Jeremáyà, ojú ìwé 68-69

    Ilé Ìṣọ́,

    3/15/2007, ojú ìwé 9-10

    12/1/2003, ojú ìwé 32

Jeremáyà 2:15

Àlàyé ìsàlẹ́ ìwé

  • *

    Tàbí “ọmọ kìnnìún tó tó ọdẹ ṣe (onígọ̀gọ̀).”

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +Ais 5:29; Jer 4:7

Jeremáyà 2:16

Àlàyé ìsàlẹ́ ìwé

  • *

    Tàbí “Mémúfísì.”

  • *

    Ní Héb., “fi ọ́ ṣe oúnjẹ jẹ ní àtàrí rẹ.”

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +Jer 46:19
  • +Jer 43:4, 7; 46:14; Isk 30:18

Jeremáyà 2:17

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +1Kr 28:9; 2Kr 7:19, 20

Jeremáyà 2:18

Àlàyé ìsàlẹ́ ìwé

  • *

    Ìyẹn, odò tó ya láti ara odò Náílì.

  • *

    Ìyẹn, odò Yúfírétì.

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +Ais 30:2; 31:1; Ida 5:6; Isk 16:26; 17:15
  • +2Ọb 16:7; Ho 5:13

Jeremáyà 2:19

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +Jer 4:18
  • +Jer 5:22

Jeremáyà 2:20

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +Le 26:13
  • +1Ọb 14:22, 23; Isk 6:13
  • +Ẹk 34:15; Isk 16:15, 16

Jeremáyà 2:21

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +Ẹk 15:17; Sm 80:8; Ais 5:1
  • +Ais 5:4

Jeremáyà 2:22

Àlàyé ìsàlẹ́ ìwé

  • *

    Tàbí “ákáláì.”

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +Jer 16:17

Jeremáyà 2:24

Àlàyé ìsàlẹ́ ìwé

  • *

    Tàbí “ohun tó wù ú lọ́kàn.”

  • *

    Ní Héb., “oṣù.”

Jeremáyà 2:25

Àlàyé ìsàlẹ́ ìwé

  • *

    Tàbí “àwọn ọlọ́run ilẹ̀ òkèèrè.”

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +Jer 18:12
  • +Ais 2:6; Jer 3:13
  • +Jer 44:17

Jeremáyà 2:26

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +Ẹsr 9:7

Jeremáyà 2:27

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +Ais 44:13
  • +2Kr 29:6; Jer 32:33
  • +Ond 10:13-15; Sm 78:34; 106:47; Ais 26:16; Ho 5:15

Jeremáyà 2:28

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +Di 32:37, 38
  • +Jer 11:13

Jeremáyà 2:29

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +Jer 5:1; 9:2; Da 9:11

Jeremáyà 2:30

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +2Kr 28:20-22; Ais 9:13
  • +Ais 1:5; Jer 5:3; Sef 3:2
  • +2Kr 36:15, 16; Ne 9:26; Iṣe 7:52

Jeremáyà 2:31

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +Di 32:15

Jeremáyà 2:32

Àlàyé ìsàlẹ́ ìwé

  • *

    Tàbí “ìborùn ìgbéyàwó.”

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +Sm 106:21; Ais 17:10; Jer 18:15; Ho 8:14

Jeremáyà 2:33

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +2Kr 33:9

Jeremáyà 2:34

Àlàyé ìsàlẹ́ ìwé

  • *

    Tàbí “àwọn ọkàn.”

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +2Ọb 21:16; Sm 106:38; Ais 10:1, 2; Mt 23:35
  • +Ẹk 22:2

Atọ́ka

  • Ìwé Ìwádìí

    Ilé Ìṣọ́,

    5/1/1997, ojú ìwé 14

Jeremáyà 2:36

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +Ais 30:3; Jer 37:7
  • +2Kr 28:20, 21

Jeremáyà 2:37

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +2Sa 13:19

Àwọn míì

Jer. 2:2Ho 2:15
Jer. 2:2Ẹk 24:3
Jer. 2:2Di 2:7
Jer. 2:3Ẹk 19:6; Di 7:6
Jer. 2:3Ẹk 17:8, 13
Jer. 2:5Ais 5:4; Mik 6:3
Jer. 2:5Di 32:21
Jer. 2:5Sm 115:4, 8
Jer. 2:6Ẹk 14:30
Jer. 2:6Di 1:1; 32:9, 10
Jer. 2:6Di 8:14, 15
Jer. 2:7Nọ 13:26, 27; Di 6:10, 11; 8:7-9
Jer. 2:7Le 18:24; Nọ 35:33; Sm 78:58; 106:38; Jer 16:18
Jer. 2:81Sa 2:12; Ida 4:13
Jer. 2:8Isk 34:7, 8
Jer. 2:81Ọb 18:19; Jer 23:13
Jer. 2:9Isk 20:35; Mik 6:2
Jer. 2:10Jẹ 10:2, 4
Jer. 2:10Jẹ 25:13; Sm 120:5; Jer 49:28
Jer. 2:11Sm 106:20
Jer. 2:13Sm 36:9; Jer 17:13; Ifi 22:1
Jer. 2:15Ais 5:29; Jer 4:7
Jer. 2:16Jer 46:19
Jer. 2:16Jer 43:4, 7; 46:14; Isk 30:18
Jer. 2:171Kr 28:9; 2Kr 7:19, 20
Jer. 2:18Ais 30:2; 31:1; Ida 5:6; Isk 16:26; 17:15
Jer. 2:182Ọb 16:7; Ho 5:13
Jer. 2:19Jer 4:18
Jer. 2:19Jer 5:22
Jer. 2:20Le 26:13
Jer. 2:201Ọb 14:22, 23; Isk 6:13
Jer. 2:20Ẹk 34:15; Isk 16:15, 16
Jer. 2:21Ẹk 15:17; Sm 80:8; Ais 5:1
Jer. 2:21Ais 5:4
Jer. 2:22Jer 16:17
Jer. 2:25Jer 18:12
Jer. 2:25Ais 2:6; Jer 3:13
Jer. 2:25Jer 44:17
Jer. 2:26Ẹsr 9:7
Jer. 2:27Ais 44:13
Jer. 2:272Kr 29:6; Jer 32:33
Jer. 2:27Ond 10:13-15; Sm 78:34; 106:47; Ais 26:16; Ho 5:15
Jer. 2:28Di 32:37, 38
Jer. 2:28Jer 11:13
Jer. 2:29Jer 5:1; 9:2; Da 9:11
Jer. 2:302Kr 28:20-22; Ais 9:13
Jer. 2:30Ais 1:5; Jer 5:3; Sef 3:2
Jer. 2:302Kr 36:15, 16; Ne 9:26; Iṣe 7:52
Jer. 2:31Di 32:15
Jer. 2:32Sm 106:21; Ais 17:10; Jer 18:15; Ho 8:14
Jer. 2:332Kr 33:9
Jer. 2:342Ọb 21:16; Sm 106:38; Ais 10:1, 2; Mt 23:35
Jer. 2:34Ẹk 22:2
Jer. 2:36Ais 30:3; Jer 37:7
Jer. 2:362Kr 28:20, 21
Jer. 2:372Sa 13:19
  • Bíbélì Mímọ́ ti Ìtumọ̀ Ayé Tuntun
  • 1
  • 2
  • 3
  • 4
  • 5
  • 6
  • 7
  • 8
  • 9
  • 10
  • 11
  • 12
  • 13
  • 14
  • 15
  • 16
  • 17
  • 18
  • 19
  • 20
  • 21
  • 22
  • 23
  • 24
  • 25
  • 26
  • 27
  • 28
  • 29
  • 30
  • 31
  • 32
  • 33
  • 34
  • 35
  • 36
  • 37
Bíbélì Mímọ́ ti Ìtumọ̀ Ayé Tuntun
Jeremáyà 2:1-37

Jeremáyà

2 Jèhófà bá mi sọ̀rọ̀, ó ní: 2 “Lọ, kí o sì kéde sétí Jerúsálẹ́mù pé, ‘Ohun tí Jèhófà sọ nìyí:

“Mo ṣì rántí dáadáa, ìfọkànsìn* tí o ní nígbà èwe rẹ,+

Ìfẹ́ tí o ní sí mi nígbà tí mò ń fẹ́ ọ sọ́nà,+

Bí o ṣe ń tẹ̀ lé mi ní aginjù,

Ní ilẹ̀ tí a kò gbin nǹkan kan sí.+

 3 Ísírẹ́lì jẹ́ mímọ́ lójú Jèhófà,+ ó jẹ́ èso tó kọ́kọ́ jáde nígbà ìkórè rẹ̀.”’

‘Ẹnikẹ́ni tó bá pa á run yóò jẹ̀bi.

Àjálù yóò dé bá wọn,’ ni Jèhófà wí.”+

 4 Gbọ́ ọ̀rọ̀ Jèhófà, ìwọ ilé Jékọ́bù

Àti gbogbo ẹ̀yin ìdílé tó wà ní ilé Ísírẹ́lì.

 5 Ohun tí Jèhófà sọ nìyí:

“Ẹ̀sùn wo ni àwọn baba ńlá yín fi kàn mí,+

Tí wọ́n fi lọ jìnnà kúrò lọ́dọ̀ mi,

Tí wọ́n ń sin àwọn òrìṣà asán,+ tí àwọn fúnra wọn sì di asán?+

 6 Wọn kò béèrè pé, ‘Ibo ni Jèhófà wà,

Ẹni tó mú wa jáde kúrò ní ilẹ̀ Íjíbítì,+

Tó mú wa gba aginjù kọjá,

Tó mú wa gba aṣálẹ̀+ àti kòtò kọjá,

Tó mú wa gba ilẹ̀ aláìlómi + àti ilẹ̀ òkùnkùn biribiri kọjá,

Tó mú wa gba ilẹ̀ tí èèyàn kì í gbà kọjá,

Ilẹ̀ tí èèyàn kì í gbé?’

 7 Lẹ́yìn náà, mo mú yín wá sí ilẹ̀ eléso,

Kí ẹ lè máa jẹ èso rẹ̀ àti àwọn ohun rere rẹ̀.+

Ṣùgbọ́n ẹ wọlé wá, ẹ sì sọ ilẹ̀ mi di ẹlẹ́gbin;

Ẹ sọ ogún mi di ohun ìríra.+

 8 Àwọn àlùfáà kò béèrè pé, ‘Ibo ni Jèhófà wà?’+

Àwọn tó ń kọ́ni ní Òfin kò sì mọ̀ mí,

Àwọn olùṣọ́ àgùntàn ṣọ̀tẹ̀ sí mi,+

Àwọn wòlíì sọ tẹ́lẹ̀ nípasẹ̀ Báálì,+

Wọ́n sì ń tẹ̀ lé àwọn tí kò lè ṣe wọ́n láǹfààní kankan.

 9 ‘Nítorí náà, màá bá yín jà lẹ́ẹ̀kan sí i,’+ ni Jèhófà wí,

‘Màá sì bá àwọn ọmọ ọmọ yín jà.’

10 ‘Ṣùgbọ́n ẹ kọjá sí etíkun* àwọn ará Kítímù+ kí ẹ sì wò ó.

Bẹ́ẹ̀ ni, ẹ ránṣẹ́ lọ sí Kídárì,+ kí ẹ sì fara balẹ̀ wò ó;

Kí ẹ sì wò ó bóyá ohun tó dà bí èyí ti ṣẹlẹ̀ rí.

11 Ǹjẹ́ orílẹ̀-èdè kan ti fi ohun tí kì í ṣe ọlọ́run rọ́pò ọlọ́run rẹ̀ rí?

Ṣùgbọ́n àwọn èèyàn mi ti fi ohun tí kò wúlò rọ́pò ògo mi.+

12 Ẹ wò ó tìyanutìyanu, ẹ̀yin ọ̀run;

Kí ẹ̀rù sì mú yín gbọ̀n rìrì,’ ni Jèhófà wí,

13 ‘Nítorí ohun búburú méjì ni àwọn èèyàn mi ṣe:

Wọ́n ti fi èmi tí mo jẹ́ orísun omi ìyè sílẹ̀,+

Wọ́n sì gbẹ́ àwọn kòtò omi* fún ara wọn,

Àwọn kòtò omi tó ti ya, tí kò lè gba omi dúró.’

14 ‘Ṣé ìránṣẹ́ ni Ísírẹ́lì àbí ẹrú tí wọ́n bí sínú agbo ilé?

Kí wá nìdí tí wọ́n fi kó ẹrù rẹ̀ lọ?

15 Àwọn ọmọ kìnnìún* ké ramúramù mọ́ ọn;+

Wọ́n gbé ohùn wọn sókè.

Wọ́n sì sọ ilẹ̀ rẹ̀ di ohun tó ń bani lẹ́rù.

Wọ́n ti sọ iná sí àwọn ìlú rẹ̀, tí kò fi sí ẹnì kankan tó ń gbé ibẹ̀.

16 Àwọn ará Nófì*+ àti àwọn Tápánésì+ ń kó ẹrù rẹ lọ.*

17 Ṣé kì í ṣe ọwọ́ rẹ lo fi fa èyí wá sórí ara rẹ

Tí o fi Jèhófà Ọlọ́run rẹ sílẹ̀+

Nígbà tó ń mú ọ rìn lọ lójú ọ̀nà?

18 Kí ló dé tí o fi fẹ́ gba ọ̀nà Íjíbítì+

Láti lọ mu omi Ṣíhórì?*

Kí sì nìdí tí o fi fẹ́ gba ọ̀nà Ásíríà+

Láti lọ mu omi Odò?*

19 Ìwà búburú rẹ ni yóò tọ́ ọ sọ́nà,

Ìwà àìṣòótọ́ rẹ ni yóò sì bá ọ wí.

Kí o lè mọ̀, kí o sì rí bí ó ti burú, tí ó sì korò tó+

Pé kí o fi Jèhófà Ọlọ́run rẹ sílẹ̀;

Ìwọ kò bẹ̀rù mi,’+ ni Olúwa Ọba Aláṣẹ, Jèhófà Ọlọ́run àwọn ọmọ ogun wí.

20 ‘Tipẹ́tipẹ́ ni mo ti ṣẹ́ àjàgà rẹ sí wẹ́wẹ́+

Mo sì já ṣẹkẹ́ṣẹkẹ̀ rẹ.

Ṣùgbọ́n, o sọ pé: “Mi ò ní sìn ọ́,”

Torí pé orí gbogbo òkè àti abẹ́ gbogbo igi tó gbẹ̀rẹ̀gẹ̀jigẹ̀+

Ni o nà gbalaja sí, tí ò ń ṣe iṣẹ́ aṣẹ́wó.+

21 Mo gbìn ọ́ bí àjàrà pupa tó dára,+ gbogbo rẹ̀ jẹ́ èso tí kò lábùkù;

Báwo lo ṣe wá di ọ̀mùnú àjàrà ilẹ̀ òkèèrè tí kò dára lójú mi?’+

22 ‘Bí o bá tiẹ̀ fi sódà* wẹ̀, tí o sì lo ọṣẹ púpọ̀,

Ẹ̀bi rẹ yóò ṣì jẹ́ àbààwọ́n níwájú mi,’+ ni Jèhófà Olúwa Ọba Aláṣẹ wí.

23 Báwo lo ṣe máa sọ pé, ‘Mi ò sọ ara mi di ẹlẹ́gbin.

Mi ò sì tẹ̀ lé Báálì’?

Wo ọ̀nà rẹ ní àfonífojì.

Wo ohun tí o ti ṣe.

O dà bí abo ọmọ ràkúnmí tó yára,

Tó ń sá lọ sá bọ̀ ní ọ̀nà rẹ̀ láìsí ohun tó ń lé e,

24 Kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́ igbó tí aginjù ti mọ́ lára,

Tó ń ṣí imú kiri nítorí ìfẹ́ ọkàn* rẹ̀.

Ta ló lè dá a dúró nígbà tí ara rẹ̀ bá wà lọ́nà láti gùn?

Kò sí ìkankan lára àwọn tó ń wá a tó máa ní láti dààmú ara rẹ̀.

Torí wọ́n á rí i ní àkókò* rẹ̀.

25 Má ṣe rìn láìwọ bàtà

Má sì jẹ́ kí òùngbẹ gbẹ ọ́.

Ṣùgbọ́n, o sọ pé, ‘Kò sí ìrètí!+

Torí ìfẹ́ àwọn àjèjì* ti kó sí mi lórí,+

Màá sì bá wọn lọ.’+

26 Bí ojú ṣe máa ń ti olè nígbà tí wọ́n bá mú un,

Bẹ́ẹ̀ ni ojú ṣe ti ilé Ísírẹ́lì,

Àwọn àti àwọn ọba wọn pẹ̀lú àwọn ìjòyè wọn

Àti àwọn àlùfáà wọn àti àwọn wòlíì wọn.+

27 Wọ́n sọ fún igi pé, ‘Ìwọ ni bàbá mi’+

Àti fún òkúta pé, ‘Ìwọ ni o bí mi.’

Wọ́n kẹ̀yìn sí mi dípò kí wọ́n kọjú sọ́dọ̀ mi.+

Ní àkókò àjálù wọn, wọ́n á sọ pé,

‘Dìde, kí o sì gbà wá!’+

28 Ní báyìí, àwọn ọlọ́run tí o ṣe fún ara rẹ dà?+

Kí wọ́n dìde bí wọ́n bá lè gbà ọ́ ní àkókò àjálù rẹ,

Torí pé bí ìlú rẹ ṣe pọ̀ ni àwọn ọlọ́run rẹ ṣe pọ̀, ìwọ Júdà.+

29 ‘Kí nìdí tí ẹ fi ń bá mi jà?

Kí nìdí tí gbogbo yín fi ń ṣọ̀tẹ̀ sí mi?’+ ni Jèhófà wí.

30 Lásán ni mo lu àwọn ọmọ yín.+

Wọn kò ní gba ìbáwí;+

Idà yín ti pa àwọn wòlíì yín,+

Bíi kìnnìún tó ń wá ẹran kiri.

31 Áà ìran yìí, ẹ kíyè sí ọ̀rọ̀ Jèhófà.

Ṣé mo ti dà bí aginjù lójú Ísírẹ́lì ni

Tàbí ilẹ̀ òkùnkùn biribiri?

Kí ló dé tí àwọn èèyàn mi yìí fi sọ pé, ‘À ń rìn kiri fàlàlà.

A kò ní wá sọ́dọ̀ rẹ mọ́’?+

32 Ǹjẹ́ wúńdíá lè gbàgbé ohun ọ̀ṣọ́ rẹ̀,

Àbí ìyàwó lè gbàgbé ọ̀já ìgbàyà* rẹ̀?

Síbẹ̀, àwọn èèyàn mi ti gbàgbé mi tipẹ́tipẹ́.+

33 Ìwọ obìnrin yìí, kí nìdí tó fi jẹ́ pé oríṣiríṣi ọgbọ́n lò ń dá láti máa wá ìfẹ́ kiri?

O ti fi ohun búburú kọ́ ara rẹ.+

34 Kódà, ẹ̀jẹ̀ àwọn* aláìní tí kò mọwọ́ mẹsẹ̀ ti ta sí ọ láṣọ,+

Kì í ṣe torí pé wọ́n ń fọ́lé ni o fi pa wọ́n;

Síbẹ̀, mo ṣì rí ẹ̀jẹ̀ wọn lára gbogbo aṣọ rẹ.+

35 Ṣùgbọ́n, o sọ pé, ‘Aláìmọwọ́-mẹsẹ̀ ni mí.

Ó dájú pé ìbínú rẹ̀ ti kúrò lórí mi.’

Ní báyìí màá dá ọ lẹ́jọ́

Torí o sọ pé, ‘Mi ò dẹ́ṣẹ̀.’

36 Kí nìdí tí o fi fojú kékeré wo ọ̀nà rẹ tí kò gún?

Ojú yóò tì ọ́ nítorí Íjíbítì,+

Bí ojú ṣe tì ọ́ nítorí Ásíríà.+

37 Nítorí èyí, ìwọ yóò káwọ́ lérí jáde,+

Torí pé Jèhófà ti kọ àwọn tí o gbọ́kàn lé;

Wọn ò ní ṣe ọ́ ní àǹfààní kankan.”

Yorùbá Publications (1987-2025)
Jáde
Wọlé
  • Yorùbá
  • Fi Ráńṣẹ́
  • Èyí tí mo fẹ́ràn jù
  • Copyright © 2025 Watch Tower Bible and Tract Society of Pennsylvania
  • Àdéhùn Nípa Lílò
  • Òfin
  • Ètò Nípa Ìsọfúnni Rẹ
  • JW.ORG
  • Wọlé
Fi Ráńṣẹ́