ÀKÁ ÌWÉ ORÍ ÍNTÁNẸ́Ẹ̀TÌ ti Watchtower
ÀKÁ ÌWÉ ORÍ ÍŃTÁNẸ́Ẹ̀TÌ
ti Watchtower
Yorùbá
ọ́
  • ẹ
  • ọ
  • ṣ
  • ń
  • ẹ́
  • ẹ̀
  • ọ́
  • ọ̀
  • BÍBÉLÌ
  • ÌTẸ̀JÁDE
  • ÌPÀDÉ
  • Diutarónómì 27
  • Bíbélì Mímọ́ ti Ìtumọ̀ Ayé Tuntun

Kò sí fídíò kankan ní apá yìí.

Má bínú, fídíò yìí kò jáde.

Ohun Tó Wà Nínú Ìwé Diutarónómì

      • Kí wọ́n kọ Òfin sára òkúta (1-10)

      • Òkè Ébálì àti Òkè Gérísímù (11-14)

      • Wọ́n tún àwọn ègún náà kà (15-26)

Diutarónómì 27:2

Àlàyé ìsàlẹ́ ìwé

  • *

    Tàbí “kùn ún lẹ́fun.”

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +Joṣ 8:30-32

Diutarónómì 27:3

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +Nọ 13:26, 27

Diutarónómì 27:4

Àlàyé ìsàlẹ́ ìwé

  • *

    Tàbí “kùn ún lẹ́fun.”

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +Di 11:29

Diutarónómì 27:5

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +Ẹk 20:25

Diutarónómì 27:7

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +Le 3:1
  • +Le 7:15
  • +Di 12:7

Diutarónómì 27:8

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +Ẹk 24:12

Diutarónómì 27:9

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +Ẹk 19:5; Di 26:18

Diutarónómì 27:10

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +1Ọb 2:3; Mt 19:17; 1Jo 5:3

Diutarónómì 27:12

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +Di 11:29

Atọ́ka

  • Ìwé Ìwádìí

    Ilé Ìṣọ́,

    2/1/1997, ojú ìwé 30-31

    6/15/1996, ojú ìwé 14

Diutarónómì 27:13

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +Joṣ 8:33

Atọ́ka

  • Ìwé Ìwádìí

    Ilé Ìṣọ́,

    2/1/1997, ojú ìwé 30-31

    6/15/1996, ojú ìwé 14

Diutarónómì 27:14

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +Di 33:10

Atọ́ka

  • Ìwé Ìwádìí

    Ilé-Ìṣọ́nà,

    6/15/1996, ojú ìwé 14

Diutarónómì 27:15

Àlàyé ìsàlẹ́ ìwé

  • *

    Tàbí “ère dídà.”

  • *

    Tàbí “oníṣẹ́ igi àti irin.”

  • *

    Tàbí “Bẹ́ẹ̀ ni kó rí.”

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +Ẹk 20:4; Di 4:15, 16; Ais 44:9
  • +Ẹk 34:17; Le 19:4
  • +Di 7:25; 29:17

Diutarónómì 27:16

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +Ẹk 20:12; Di 21:18-21; Owe 20:20; 30:17; Mt 15:4

Atọ́ka

  • Ìwé Ìwádìí

    Ilé Ìṣọ́,

    2/1/1997, ojú ìwé 30-31

Diutarónómì 27:17

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +Di 19:14; Owe 23:10

Atọ́ka

  • Ìwé Ìwádìí

    Àwọn Ìtẹ̀jáde Tá A Tọ́ka sí Nínú Ìwé Ìpàdé, 7/2021,

    Ilé Ìṣọ́,

    2/1/1997, ojú ìwé 30-31

Diutarónómì 27:18

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +Le 19:14

Diutarónómì 27:19

Àlàyé ìsàlẹ́ ìwé

  • *

    Tàbí “aláìlóbìí.”

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +Di 16:20; Owe 17:23; Mik 3:11
  • +Ẹk 22:21, 22; Di 10:17, 18; Mal 3:5; Jem 1:27

Diutarónómì 27:20

Àlàyé ìsàlẹ́ ìwé

  • *

    Ní Héb., “ṣí aṣọ lára bàbá rẹ̀.”

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +Le 18:8; 1Kọ 5:1

Diutarónómì 27:21

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +Ẹk 22:19; Le 18:23; 20:15

Diutarónómì 27:22

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +Le 18:9; 20:17

Diutarónómì 27:23

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +Le 18:17; 20:14

Diutarónómì 27:24

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +Ẹk 20:13; 21:12; Nọ 35:31

Diutarónómì 27:25

Àlàyé ìsàlẹ́ ìwé

  • *

    Tàbí “láti ṣá ẹni tí kò mọwọ́ mẹsẹ̀ balẹ̀.”

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +Mt 27:3, 4

Diutarónómì 27:26

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +Di 28:15; Ga 3:10

Àwọn míì

Diu. 27:2Joṣ 8:30-32
Diu. 27:3Nọ 13:26, 27
Diu. 27:4Di 11:29
Diu. 27:5Ẹk 20:25
Diu. 27:7Le 3:1
Diu. 27:7Le 7:15
Diu. 27:7Di 12:7
Diu. 27:8Ẹk 24:12
Diu. 27:9Ẹk 19:5; Di 26:18
Diu. 27:101Ọb 2:3; Mt 19:17; 1Jo 5:3
Diu. 27:12Di 11:29
Diu. 27:13Joṣ 8:33
Diu. 27:14Di 33:10
Diu. 27:15Ẹk 20:4; Di 4:15, 16; Ais 44:9
Diu. 27:15Ẹk 34:17; Le 19:4
Diu. 27:15Di 7:25; 29:17
Diu. 27:16Ẹk 20:12; Di 21:18-21; Owe 20:20; 30:17; Mt 15:4
Diu. 27:17Di 19:14; Owe 23:10
Diu. 27:18Le 19:14
Diu. 27:19Di 16:20; Owe 17:23; Mik 3:11
Diu. 27:19Ẹk 22:21, 22; Di 10:17, 18; Mal 3:5; Jem 1:27
Diu. 27:20Le 18:8; 1Kọ 5:1
Diu. 27:21Ẹk 22:19; Le 18:23; 20:15
Diu. 27:22Le 18:9; 20:17
Diu. 27:23Le 18:17; 20:14
Diu. 27:24Ẹk 20:13; 21:12; Nọ 35:31
Diu. 27:25Mt 27:3, 4
Diu. 27:26Di 28:15; Ga 3:10
  • Bíbélì Mímọ́ ti Ìtumọ̀ Ayé Tuntun
  • 1
  • 2
  • 3
  • 4
  • 5
  • 6
  • 7
  • 8
  • 9
  • 10
  • 11
  • 12
  • 13
  • 14
  • 15
  • 16
  • 17
  • 18
  • 19
  • 20
  • 21
  • 22
  • 23
  • 24
  • 25
  • 26
Bíbélì Mímọ́ ti Ìtumọ̀ Ayé Tuntun
Diutarónómì 27:1-26

Diutarónómì

27 Mósè pẹ̀lú àwọn àgbààgbà Ísírẹ́lì wá pàṣẹ fún àwọn èèyàn náà pé: “Kí ẹ pa gbogbo àṣẹ tí mò ń pa fún yín lónìí mọ́. 2 Ní ọjọ́ tí ẹ bá sọdá Jọ́dánì sí ilẹ̀ tí Jèhófà Ọlọ́run yín fẹ́ fún yín, kí ẹ to àwọn òkúta ńláńlá jọ, kí ẹ sì rẹ́ ẹ.*+ 3 Kí ẹ wá kọ gbogbo ọ̀rọ̀ Òfin yìí sára wọn tí ẹ bá ti sọdá, kí ẹ lè wọ ilẹ̀ tí Jèhófà Ọlọ́run yín fẹ́ fún yín, ilẹ̀ tí wàrà àti oyin ti ń ṣàn, bí Jèhófà Ọlọ́run àwọn baba ńlá yín ṣe ṣèlérí fún yín gẹ́lẹ́.+ 4 Tí ẹ bá ti sọdá Jọ́dánì, kí ẹ to àwọn òkúta yìí sórí Òkè Ébálì,+ kí ẹ sì rẹ́ ẹ,* bí mo ṣe ń pa á láṣẹ fún yín lónìí. 5 Kí ẹ tún mọ pẹpẹ kan síbẹ̀ fún Jèhófà Ọlọ́run yín, òkúta ni kí ẹ fi mọ ọ́n. Ẹ má fi irin gbẹ́ ẹ.+ 6 Odindi òkúta ni kí ẹ fi mọ pẹpẹ Jèhófà Ọlọ́run yín, kí ẹ sì rú àwọn ẹbọ sísun sí Jèhófà Ọlọ́run yín lórí rẹ̀. 7 Kí ẹ rú àwọn ẹbọ ìrẹ́pọ̀,+ kí ẹ jẹ ẹ́ níbẹ̀,+ kí ẹ sì máa yọ̀ níwájú Jèhófà Ọlọ́run yín.+ 8 Kí ẹ kọ gbogbo ọ̀rọ̀ inú Òfin yìí sára àwọn òkúta náà, kó sì hàn kedere.”+

9 Mósè àtàwọn àlùfáà tí wọ́n jẹ́ ọmọ Léfì wá sọ fún gbogbo Ísírẹ́lì pé: “Ẹ dákẹ́ jẹ́ẹ́, kí ẹ sì fetí sílẹ̀, ẹ̀yin ọmọ Ísírẹ́lì. Ẹ ti di èèyàn Jèhófà Ọlọ́run yín lónìí.+ 10 Kí ẹ máa fetí sí ohùn Jèhófà Ọlọ́run yín, kí ẹ máa pa àwọn àṣẹ+ àti ìlànà rẹ̀ mọ́, èyí tí mò ń pa láṣẹ fún yín lónìí.”

11 Mósè pàṣẹ fún àwọn èèyàn náà lọ́jọ́ yẹn pé: 12 “Àwọn ẹ̀yà yìí ló máa dúró lórí Òkè Gérísímù+ láti súre fún àwọn èèyàn náà tí ẹ bá ti sọdá Jọ́dánì: Síméónì, Léfì, Júdà, Ísákà, Jósẹ́fù àti Bẹ́ńjámínì. 13 Àwọn ẹ̀yà yìí ló sì máa dúró lórí Òkè Ébálì+ láti kéde ègún: Rúbẹ́nì, Gádì, Áṣérì, Sébúlúnì, Dánì àti Náfútálì. 14 Kí àwọn ọmọ Léfì gbóhùn sókè dáadáa, kí wọ́n sì sọ fún gbogbo Ísírẹ́lì pé:+

15 “‘Ègún ni fún ẹni tó bá gbẹ́ ère+ tàbí tó ṣe ère onírin,*+ tó jẹ́ ohun ìríra lójú Jèhófà,+ iṣẹ́ ọwọ́ oníṣẹ́ ọnà,* tó sì gbé e pa mọ́.’ (Kí gbogbo èèyàn sì sọ pé, ‘Àmín!’*)

16 “‘Ègún ni fún ẹni tó bá fojú kéré bàbá àti ìyá rẹ̀.’+ (Kí gbogbo èèyàn sì sọ pé, ‘Àmín!’)

17 “‘Ègún ni fún ẹni tó bá sún ààlà ọmọnìkejì rẹ̀.’+ (Kí gbogbo èèyàn sì sọ pé, ‘Àmín!’)

18 “‘Ègún ni fún ẹni tó bá mú kí afọ́jú ṣìnà.’+ (Kí gbogbo èèyàn sì sọ pé, ‘Àmín!’)

19 “‘Ègún ni fún ẹni tó bá ṣe èrú nínú ẹjọ́+ àjèjì, ọmọ aláìníbaba* tàbí opó.’+ (Kí gbogbo èèyàn sì sọ pé, ‘Àmín!’)

20 “‘Ègún ni fún ẹni tó bá bá ìyàwó bàbá rẹ̀ sùn, torí ó ti dójú ti bàbá rẹ̀.’*+ (Kí gbogbo èèyàn sì sọ pé, ‘Àmín!’)

21 “‘Ègún ni fún ẹni tó bá bá ẹranko èyíkéyìí lò pọ̀.’+ (Kí gbogbo èèyàn sì sọ pé, ‘Àmín!’)

22 “‘Ègún ni fún ẹni tó bá bá arábìnrin rẹ̀ sùn, ì báà jẹ́ ọmọ bàbá rẹ̀ tàbí ọmọ ìyá rẹ̀.’+ (Kí gbogbo èèyàn sì sọ pé, ‘Àmín!’)

23 “‘Ègún ni fún ẹni tó bá bá ìyá ìyàwó rẹ̀ sùn.’+ (Kí gbogbo èèyàn sì sọ pé, ‘Àmín!’)

24 “‘Ègún ni fún ẹni tó bá lúgọ de ọmọnìkejì rẹ̀, tó sì pa á.’+ (Kí gbogbo èèyàn sì sọ pé, ‘Àmín!’)

25 “‘Ègún ni fún ẹni tó bá gba àbẹ̀tẹ́lẹ̀ láti pa ẹni tí kò mọwọ́ mẹsẹ̀.’*+ (Kí gbogbo èèyàn sì sọ pé, ‘Àmín!’)

26 “‘Ègún ni fún ẹni tí kò bá pa àwọn ọ̀rọ̀ inú Òfin yìí mọ́ láti fi hàn pé ó fara mọ́ wọn.’+ (Kí gbogbo èèyàn sì sọ pé, ‘Àmín!’)

Yorùbá Publications (1987-2025)
Jáde
Wọlé
  • Yorùbá
  • Fi Ráńṣẹ́
  • Èyí tí mo fẹ́ràn jù
  • Copyright © 2025 Watch Tower Bible and Tract Society of Pennsylvania
  • Àdéhùn Nípa Lílò
  • Òfin
  • Ètò Nípa Ìsọfúnni Rẹ
  • JW.ORG
  • Wọlé
Fi Ráńṣẹ́