ÀKÁ ÌWÉ ORÍ ÍNTÁNẸ́Ẹ̀TÌ ti Watchtower
ÀKÁ ÌWÉ ORÍ ÍŃTÁNẸ́Ẹ̀TÌ
ti Watchtower
Yorùbá
ọ́
  • ẹ
  • ọ
  • ṣ
  • ń
  • ẹ́
  • ẹ̀
  • ọ́
  • ọ̀
  • BÍBÉLÌ
  • ÌTẸ̀JÁDE
  • ÌPÀDÉ
  • Sáàmù 143
  • Bíbélì Mímọ́ ti Ìtumọ̀ Ayé Tuntun

Kò sí fídíò kankan ní apá yìí.

Má bínú, fídíò yìí kò jáde.

Ohun Tó Wà Nínú Ìwé Sáàmù

      • Mò ń wá Ọlọ́run bí ilẹ̀ gbígbẹ ṣe ń wá òjò

        • ‘Mò ń ronú lórí àwọn iṣẹ́ rẹ’ (5)

        • “Kọ́ mi láti máa ṣe ìfẹ́ rẹ” (10)

        • ‘Kí ẹ̀mí dáradára rẹ máa darí mi’ (10)

Sáàmù 143:1

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +Sm 65:2

Atọ́ka

  • Ìwé Ìwádìí

    Ilé-Ìṣọ́nà,

    12/15/1996, ojú ìwé 11

Sáàmù 143:2

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +Job 9:2; Sm 130:3; Onw 7:20; Ro 3:20; Ga 2:16; 1Jo 1:10

Atọ́ka

  • Ìwé Ìwádìí

    Ilé-Ìṣọ́nà,

    12/15/1996, ojú ìwé 11

Sáàmù 143:3

Àlàyé ìsàlẹ́ ìwé

  • *

    Tàbí “ọkàn mi.”

Atọ́ka

  • Ìwé Ìwádìí

    Ilé-Ìṣọ́nà,

    12/15/1996, ojú ìwé 11

Sáàmù 143:4

Àlàyé ìsàlẹ́ ìwé

  • *

    Tàbí “Mi ò lágbára mọ́.”

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +Sm 142:3
  • +Sm 102:4

Atọ́ka

  • Ìwé Ìwádìí

    Ilé-Ìṣọ́nà,

    12/15/1996, ojú ìwé 11

Sáàmù 143:5

Àlàyé ìsàlẹ́ ìwé

  • *

    Tàbí “kẹ́kọ̀ọ́ nípa.”

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +Sm 77:5, 6, 11, 12; 111:2, 3

Atọ́ka

  • Ìwé Ìwádìí

    Ilé-Ìṣọ́nà,

    12/15/1996, ojú ìwé 11-13

Sáàmù 143:6

Àlàyé ìsàlẹ́ ìwé

  • *

    Tàbí “Ọkàn mi.”

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +Sm 63:1

Atọ́ka

  • Ìwé Ìwádìí

    Ilé-Ìṣọ́nà,

    12/15/1996, ojú ìwé 13

Sáàmù 143:7

Àlàyé ìsàlẹ́ ìwé

  • *

    Ní Héb., “Ẹ̀mí.”

  • *

    Tàbí “sàréè.”

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +Sm 40:13; 70:5
  • +Sm 142:3
  • +Sm 27:9
  • +Sm 28:1

Atọ́ka

  • Ìwé Ìwádìí

    Ilé-Ìṣọ́nà,

    12/15/1996, ojú ìwé 13

Sáàmù 143:8

Àlàyé ìsàlẹ́ ìwé

  • *

    Tàbí “ìwọ ni mo gbé ọkàn mi sókè sí.”

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +Sm 5:8; Owe 3:6

Atọ́ka

  • Ìwé Ìwádìí

    Ilé Ìṣọ́,

    1/15/2010, ojú ìwé 21

    12/15/1996, ojú ìwé 13

Sáàmù 143:9

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +Sm 59:1; 61:3, 4; 91:1

Atọ́ka

  • Ìwé Ìwádìí

    Ilé-Ìṣọ́nà,

    12/15/1996, ojú ìwé 13

Sáàmù 143:10

Àlàyé ìsàlẹ́ ìwé

  • *

    Tàbí “ilẹ̀ adúróṣinṣin.”

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +Sm 25:4

Atọ́ka

  • Ìwé Ìwádìí

    Ilé-Ìṣọ́nà,

    12/15/1996, ojú ìwé 14-19

    9/15/1992, ojú ìwé 14-15

Sáàmù 143:11

Àlàyé ìsàlẹ́ ìwé

  • *

    Tàbí “Gba ọkàn mi.”

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +Sm 31:1

Sáàmù 143:12

Àlàyé ìsàlẹ́ ìwé

  • *

    Ní Héb., “lẹ́nu mọ́.”

  • *

    Tàbí “ọkàn mi.”

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +1Sa 25:29; 26:9, 10
  • +1Sa 24:12
  • +Sm 89:20

Àwọn míì

Sm 143:1Sm 65:2
Sm 143:2Job 9:2; Sm 130:3; Onw 7:20; Ro 3:20; Ga 2:16; 1Jo 1:10
Sm 143:4Sm 142:3
Sm 143:4Sm 102:4
Sm 143:5Sm 77:5, 6, 11, 12; 111:2, 3
Sm 143:6Sm 63:1
Sm 143:7Sm 40:13; 70:5
Sm 143:7Sm 142:3
Sm 143:7Sm 27:9
Sm 143:7Sm 28:1
Sm 143:8Sm 5:8; Owe 3:6
Sm 143:9Sm 59:1; 61:3, 4; 91:1
Sm 143:10Sm 25:4
Sm 143:11Sm 31:1
Sm 143:121Sa 25:29; 26:9, 10
Sm 143:121Sa 24:12
Sm 143:12Sm 89:20
  • Bíbélì Mímọ́ ti Ìtumọ̀ Ayé Tuntun
  • 1
  • 2
  • 3
  • 4
  • 5
  • 6
  • 7
  • 8
  • 9
  • 10
  • 11
  • 12
Bíbélì Mímọ́ ti Ìtumọ̀ Ayé Tuntun
Sáàmù 143:1-12

Sáàmù

Orin Dáfídì.

143 Jèhófà, gbọ́ àdúrà mi;+

Gbọ́ ẹ̀bẹ̀ mi fún ìrànlọ́wọ́.

Dá mi lóhùn nínú òtítọ́ rẹ àti òdodo rẹ.

2 Má ṣe bá ìránṣẹ́ rẹ ṣẹjọ́,

Nítorí kò sí alààyè kankan tó lè jẹ́ olódodo níwájú rẹ.+

3 Nítorí ọ̀tá ń lépa mi;*

Ó ti tẹ ẹ̀mí mi mọ́lẹ̀.

Ó ti mú kí n máa gbé inú òkùnkùn bí àwọn tó ti kú tipẹ́tipẹ́.

4 Àárẹ̀ mú ẹ̀mí mi;*+

Ọkàn mi kú tipiri nínú mi.+

5 Mo rántí àwọn ọjọ́ àtijọ́;

Mo ṣe àṣàrò lórí gbogbo iṣẹ́ rẹ;+

Ó ń yá mi lára láti máa ronú lórí* iṣẹ́ ọwọ́ rẹ.

6 Mo tẹ́ ọwọ́ mi sí ọ;

Mò* ń wá ọ bí ilẹ̀ tó gbẹ táútáú ṣe ń wá òjò.+ (Sélà)

7 Jọ̀ọ́ Jèhófà, tètè dá mi lóhùn;+

Agbára* mi ti tán.+

Má fi ojú rẹ pa mọ́ fún mi,+

Kí n má bàa dà bí àwọn tó ń lọ sínú kòtò.*+

8 Ní àárọ̀, jẹ́ kí n gbọ́ nípa ìfẹ́ rẹ tí kì í yẹ̀,

Nítorí mo gbẹ́kẹ̀ lé ọ.

Jẹ́ kí n mọ ọ̀nà tó yẹ kí n máa rìn,+

Nítorí ìwọ ni mo yíjú sí.*

9 Gbà mí lọ́wọ́ àwọn ọ̀tá mi, Jèhófà.

Ààbò rẹ ni mò ń wá.+

10 Kọ́ mi láti máa ṣe ìfẹ́ rẹ,+

Nítorí ìwọ ni Ọlọ́run mi.

Ẹ̀mí rẹ dára;

Kí ó máa darí mi ní ilẹ̀ tó tẹ́jú.*

11 Jèhófà, jọ̀wọ́ jẹ́ kí n máa wà láàyè nítorí orúkọ rẹ.

Gbà mí* nínú wàhálà nítorí òdodo rẹ.+

12 Pa àwọn ọ̀tá mi rẹ́*+ nítorí ìfẹ́ rẹ tí kì í yẹ̀;

Pa gbogbo àwọn tó ń halẹ̀ mọ́ mi* run,+

Nítorí ìránṣẹ́ rẹ ni mí.+

Yorùbá Publications (1987-2025)
Jáde
Wọlé
  • Yorùbá
  • Fi Ráńṣẹ́
  • Èyí tí mo fẹ́ràn jù
  • Copyright © 2025 Watch Tower Bible and Tract Society of Pennsylvania
  • Àdéhùn Nípa Lílò
  • Òfin
  • Ètò Nípa Ìsọfúnni Rẹ
  • JW.ORG
  • Wọlé
Fi Ráńṣẹ́