ÀKÁ ÌWÉ ORÍ ÍNTÁNẸ́Ẹ̀TÌ ti Watchtower
ÀKÁ ÌWÉ ORÍ ÍŃTÁNẸ́Ẹ̀TÌ
ti Watchtower
Yorùbá
ọ́
  • ẹ
  • ọ
  • ṣ
  • ń
  • ẹ́
  • ẹ̀
  • ọ́
  • ọ̀
  • BÍBÉLÌ
  • ÌTẸ̀JÁDE
  • ÌPÀDÉ
  • Jóṣúà 21
  • Bíbélì Mímọ́ ti Ìtumọ̀ Ayé Tuntun

Kò sí fídíò kankan ní apá yìí.

Má bínú, fídíò yìí kò jáde.

Ohun Tó Wà Nínú Ìwé Jóṣúà

      • Àwọn ìlú tí wọ́n fún àwọn ọmọ Léfì (1-42)

        • Ìlú àwọn àtọmọdọ́mọ Áárónì (9-19)

        • Ìlú àwọn ọmọ Kóhátì yòókù (20-26)

        • Ìlú àwọn ọmọ Gẹ́ṣónì (27-33)

        • Ìlú àwọn ọmọ Mérárì (34-40)

      • Àwọn ìlérí Jèhófà ṣẹ (43-45)

Jóṣúà 21:1

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +Nọ 34:17

Jóṣúà 21:2

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +Joṣ 18:1
  • +Le 25:33, 34; Nọ 35:2-4; Joṣ 14:4

Jóṣúà 21:3

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +Nọ 35:8
  • +Jẹ 49:5, 7

Jóṣúà 21:4

Àlàyé ìsàlẹ́ ìwé

  • *

    Tàbí “wọ́n sì pín.”

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +Jẹ 46:11; Nọ 3:27-31
  • +1Kr 6:54, 55
  • +Joṣ 19:1
  • +1Kr 6:60, 64

Jóṣúà 21:5

Àlàyé ìsàlẹ́ ìwé

  • *

    Tàbí “Wọ́n sì fi kèké pín ilẹ̀ fún.”

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +1Kr 6:66
  • +1Kr 6:61, 70

Jóṣúà 21:6

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +Ẹk 6:17; Nọ 3:21, 22
  • +Nọ 32:33; 1Kr 6:62

Jóṣúà 21:7

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +Ẹk 6:19
  • +1Kr 6:63

Jóṣúà 21:8

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +Nọ 35:2, 5

Jóṣúà 21:9

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +1Kr 6:64, 65

Jóṣúà 21:11

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +Jẹ 23:2; 35:27; Joṣ 15:13, 14; 20:7; Ond 1:10
  • +2Sa 2:1; 15:10; 1Kr 6:54-56

Jóṣúà 21:12

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +Ond 1:20

Jóṣúà 21:13

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +Nọ 35:6, 15
  • +Joṣ 15:20, 54
  • +Joṣ 15:20, 42

Jóṣúà 21:14

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +Joṣ 15:20, 48
  • +Joṣ 15:20, 50

Jóṣúà 21:15

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +Joṣ 15:20, 51
  • +Joṣ 15:20, 49; 1Kr 6:57, 58

Jóṣúà 21:16

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +Joṣ 19:1, 7
  • +Joṣ 15:20, 55

Jóṣúà 21:17

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +Joṣ 9:3; 18:21, 25
  • +1Kr 6:57, 60

Jóṣúà 21:18

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +Jer 1:1

Jóṣúà 21:19

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +Le 25:33, 34; Nọ 35:4

Jóṣúà 21:21

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +Nọ 35:11, 15
  • +Joṣ 20:7; 1Ọb 12:1
  • +Joṣ 16:10

Jóṣúà 21:22

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +Joṣ 16:1, 3; 18:11, 13

Jóṣúà 21:24

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +Joṣ 10:12; Ond 1:35; 2Kr 28:18

Jóṣúà 21:25

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +Joṣ 17:11

Jóṣúà 21:27

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +Joṣ 21:6
  • +1Kr 6:71

Jóṣúà 21:28

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +1Kr 6:72, 73
  • +Joṣ 19:12, 16

Jóṣúà 21:30

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +1Kr 6:74, 75

Jóṣúà 21:31

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +Joṣ 19:25, 31
  • +Joṣ 19:28, 31; Ond 1:31

Jóṣúà 21:32

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +Nọ 35:14, 15
  • +Joṣ 20:7

Jóṣúà 21:34

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +Joṣ 21:7
  • +1Kr 6:77
  • +Joṣ 19:10, 11

Jóṣúà 21:35

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +Ond 1:30

Jóṣúà 21:36

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +Di 4:41-43; Joṣ 20:8
  • +1Kr 6:78, 79

Jóṣúà 21:38

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +1Kr 6:80, 81
  • +Joṣ 20:8, 9; 1Ọb 22:3
  • +Jẹ 32:2; 2Sa 2:8

Jóṣúà 21:39

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +Nọ 21:26; 32:37
  • +Nọ 32:1

Jóṣúà 21:41

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +Nọ 35:5, 7

Jóṣúà 21:43

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +Jẹ 13:14, 15; 15:18; 26:3; 28:4
  • +Ẹk 23:30

Atọ́ka

  • Ìwé Ìwádìí

    Àwọn Ìtẹ̀jáde Tá A Tọ́ka sí Nínú Ìwé Ìpàdé, 9/2021,

Jóṣúà 21:44

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +Ẹk 33:14; Di 12:10; Joṣ 1:13; 11:23; 22:4
  • +Di 28:7
  • +Di 7:24; 31:3

Atọ́ka

  • Ìwé Ìwádìí

    Àwọn Ìtẹ̀jáde Tá A Tọ́ka sí Nínú Ìwé Ìpàdé, 9/2021,

Jóṣúà 21:45

Àlàyé ìsàlẹ́ ìwé

  • *

    Tàbí “ọ̀rọ̀.”

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +Joṣ 23:14; 1Ọb 8:56; Heb 6:18

Atọ́ka

  • Ìwé Ìwádìí

    Àwọn Ìtẹ̀jáde Tá A Tọ́ka sí Nínú Ìwé Ìpàdé, 9/2021,

Àwọn míì

Jóṣ. 21:1Nọ 34:17
Jóṣ. 21:2Joṣ 18:1
Jóṣ. 21:2Le 25:33, 34; Nọ 35:2-4; Joṣ 14:4
Jóṣ. 21:3Nọ 35:8
Jóṣ. 21:3Jẹ 49:5, 7
Jóṣ. 21:4Jẹ 46:11; Nọ 3:27-31
Jóṣ. 21:41Kr 6:54, 55
Jóṣ. 21:4Joṣ 19:1
Jóṣ. 21:41Kr 6:60, 64
Jóṣ. 21:51Kr 6:66
Jóṣ. 21:51Kr 6:61, 70
Jóṣ. 21:6Ẹk 6:17; Nọ 3:21, 22
Jóṣ. 21:6Nọ 32:33; 1Kr 6:62
Jóṣ. 21:7Ẹk 6:19
Jóṣ. 21:71Kr 6:63
Jóṣ. 21:8Nọ 35:2, 5
Jóṣ. 21:91Kr 6:64, 65
Jóṣ. 21:11Jẹ 23:2; 35:27; Joṣ 15:13, 14; 20:7; Ond 1:10
Jóṣ. 21:112Sa 2:1; 15:10; 1Kr 6:54-56
Jóṣ. 21:12Ond 1:20
Jóṣ. 21:13Nọ 35:6, 15
Jóṣ. 21:13Joṣ 15:20, 54
Jóṣ. 21:13Joṣ 15:20, 42
Jóṣ. 21:14Joṣ 15:20, 48
Jóṣ. 21:14Joṣ 15:20, 50
Jóṣ. 21:15Joṣ 15:20, 51
Jóṣ. 21:15Joṣ 15:20, 49; 1Kr 6:57, 58
Jóṣ. 21:16Joṣ 19:1, 7
Jóṣ. 21:16Joṣ 15:20, 55
Jóṣ. 21:17Joṣ 9:3; 18:21, 25
Jóṣ. 21:171Kr 6:57, 60
Jóṣ. 21:18Jer 1:1
Jóṣ. 21:19Le 25:33, 34; Nọ 35:4
Jóṣ. 21:21Nọ 35:11, 15
Jóṣ. 21:21Joṣ 20:7; 1Ọb 12:1
Jóṣ. 21:21Joṣ 16:10
Jóṣ. 21:22Joṣ 16:1, 3; 18:11, 13
Jóṣ. 21:24Joṣ 10:12; Ond 1:35; 2Kr 28:18
Jóṣ. 21:25Joṣ 17:11
Jóṣ. 21:27Joṣ 21:6
Jóṣ. 21:271Kr 6:71
Jóṣ. 21:281Kr 6:72, 73
Jóṣ. 21:28Joṣ 19:12, 16
Jóṣ. 21:301Kr 6:74, 75
Jóṣ. 21:31Joṣ 19:25, 31
Jóṣ. 21:31Joṣ 19:28, 31; Ond 1:31
Jóṣ. 21:32Nọ 35:14, 15
Jóṣ. 21:32Joṣ 20:7
Jóṣ. 21:34Joṣ 21:7
Jóṣ. 21:341Kr 6:77
Jóṣ. 21:34Joṣ 19:10, 11
Jóṣ. 21:35Ond 1:30
Jóṣ. 21:36Di 4:41-43; Joṣ 20:8
Jóṣ. 21:361Kr 6:78, 79
Jóṣ. 21:381Kr 6:80, 81
Jóṣ. 21:38Joṣ 20:8, 9; 1Ọb 22:3
Jóṣ. 21:38Jẹ 32:2; 2Sa 2:8
Jóṣ. 21:39Nọ 21:26; 32:37
Jóṣ. 21:39Nọ 32:1
Jóṣ. 21:41Nọ 35:5, 7
Jóṣ. 21:43Jẹ 13:14, 15; 15:18; 26:3; 28:4
Jóṣ. 21:43Ẹk 23:30
Jóṣ. 21:44Ẹk 33:14; Di 12:10; Joṣ 1:13; 11:23; 22:4
Jóṣ. 21:44Di 28:7
Jóṣ. 21:44Di 7:24; 31:3
Jóṣ. 21:45Joṣ 23:14; 1Ọb 8:56; Heb 6:18
  • Bíbélì Mímọ́ ti Ìtumọ̀ Ayé Tuntun
  • 1
  • 2
  • 3
  • 4
  • 5
  • 6
  • 7
  • 8
  • 9
  • 10
  • 11
  • 12
  • 13
  • 14
  • 15
  • 16
  • 17
  • 18
  • 19
  • 20
  • 21
  • 22
  • 23
  • 24
  • 25
  • 26
  • 27
  • 28
  • 29
  • 30
  • 31
  • 32
  • 33
  • 34
  • 35
  • 36
  • 37
  • 38
  • 39
  • 40
  • 41
  • 42
  • 43
  • 44
  • 45
Bíbélì Mímọ́ ti Ìtumọ̀ Ayé Tuntun
Jóṣúà 21:1-45

Jóṣúà

21 Àwọn olórí agbo ilé bàbá àwọn ọmọ Léfì wá lọ bá àlùfáà Élíásárì+ àti Jóṣúà ọmọ Núnì pẹ̀lú àwọn olórí agbo ilé bàbá nínú ẹ̀yà àwọn ọmọ Ísírẹ́lì, 2 wọ́n sì sọ fún wọn ní Ṣílò+ ní ilẹ̀ Kénáánì pé: “Jèhófà pa á láṣẹ nípasẹ̀ Mósè pé kí wọ́n fún wa ní àwọn ìlú tí a máa gbé, pẹ̀lú àwọn ibi ìjẹko wọn fún àwọn ẹran ọ̀sìn wa.”+ 3 Torí náà, bí Jèhófà ṣe pa á láṣẹ, àwọn ọmọ Ísírẹ́lì fún àwọn ọmọ Léfì ní àwọn ìlú yìí+ àtàwọn ibi ìjẹko wọn látinú ogún tiwọn.+

4 Kèké mú ìdílé àwọn ọmọ Kóhátì,+ wọ́n sì fi kèké pín* ìlú mẹ́tàlá (13) fún àwọn ọmọ Léfì tí wọ́n jẹ́ àtọmọdọ́mọ àlùfáà Áárónì, látinú ìpín ẹ̀yà Júdà,+ ẹ̀yà Síméónì+ àti ẹ̀yà Bẹ́ńjámínì.+

5 Wọ́n sì fún* àwọn ọmọ Kóhátì tó ṣẹ́ kù ní ìlú mẹ́wàá, látinú ìpín àwọn ìdílé ẹ̀yà Éfúrémù,+ ẹ̀yà Dánì àti ààbọ̀ ẹ̀yà Mánásè.+

6 Wọ́n fún àwọn ọmọ Gẹ́ṣónì+ ní ìlú mẹ́tàlá (13) látinú ìpín àwọn ìdílé ẹ̀yà Ísákà, ẹ̀yà Áṣérì, ẹ̀yà Náfútálì àti ààbọ̀ ẹ̀yà Mánásè ní Báṣánì.+

7 Wọ́n fún àwọn ọmọ Mérárì+ ní ìlú méjìlá (12) ní ìdílé-ìdílé látinú ìpín ẹ̀yà Rúbẹ́nì, ẹ̀yà Gádì àti ẹ̀yà Sébúlúnì.+

8 Bí àwọn ọmọ Ísírẹ́lì ṣe fi kèké pín àwọn ìlú yìí àtàwọn ibi ìjẹko wọn fún àwọn ọmọ Léfì nìyẹn, bí Jèhófà ṣe pa á láṣẹ nípasẹ̀ Mósè.+

9 Torí náà, wọ́n fún wọn ní àwọn ìlú tí a dárúkọ yìí látinú ìpín ẹ̀yà Júdà àti ẹ̀yà Síméónì,+ 10 wọ́n sì fún àwọn ọmọ Áárónì, tó wá látinú ìdílé Kóhátì ọmọ Léfì, torí àwọn ni kèké kọ́kọ́ mú. 11 Wọ́n fún wọn ní Kiriati-ábà+ (Ábà ni bàbá Ánákì), ìyẹn Hébúrónì,+ ní agbègbè olókè Júdà àti àwọn ibi ìjẹko tó yí i ká. 12 Àmọ́ Kélẹ́bù ọmọ Jéfúnè ni wọ́n fún ní pápá tó wà ní ìlú náà pẹ̀lú ìgbèríko rẹ̀ pé kó jẹ́ ohun ìní rẹ̀.+

13 Wọ́n fún àwọn ọmọ àlùfáà Áárónì ní ìlú ààbò tí ẹni tó bá pààyàn máa sá lọ,+ ìyẹn Hébúrónì+ pẹ̀lú àwọn ibi ìjẹko rẹ̀ àti Líbínà+ pẹ̀lú àwọn ibi ìjẹko rẹ̀, 14 Játírì+ pẹ̀lú àwọn ibi ìjẹko rẹ̀, Éṣítémóà+ pẹ̀lú àwọn ibi ìjẹko rẹ̀, 15 Hólónì+ pẹ̀lú àwọn ibi ìjẹko rẹ̀, Débírì+ pẹ̀lú àwọn ibi ìjẹko rẹ̀, 16 Áyínì+ pẹ̀lú àwọn ibi ìjẹko rẹ̀, Jútà+ pẹ̀lú àwọn ibi ìjẹko rẹ̀ àti Bẹti-ṣémẹ́ṣì pẹ̀lú àwọn ibi ìjẹko rẹ̀, ó jẹ́ ìlú mẹ́sàn-án látinú ìpín ẹ̀yà méjì yìí.

17 Látinú ìpín ẹ̀yà Bẹ́ńjámínì: Gíbíónì+ pẹ̀lú àwọn ibi ìjẹko rẹ̀, Gébà pẹ̀lú àwọn ibi ìjẹko rẹ̀,+ 18 Ánátótì+ pẹ̀lú àwọn ibi ìjẹko rẹ̀ àti Álímónì pẹ̀lú àwọn ibi ìjẹko rẹ̀, ó jẹ́ ìlú mẹ́rin.

19 Gbogbo ìlú tí wọ́n fún àwọn àtọmọdọ́mọ Áárónì, àwọn àlùfáà, jẹ́ ìlú mẹ́tàlá (13) pẹ̀lú àwọn ibi ìjẹko wọn.+

20 Wọ́n fi kèké pín àwọn ìlú fún àwọn ìdílé ọmọ Kóhátì yòókù nínú àwọn ọmọ Léfì látinú ìpín ẹ̀yà Éfúrémù. 21 Wọ́n fún wọn ní ìlú ààbò tí ẹni tó bá pààyàn máa sá lọ,+ ìyẹn Ṣékémù+ pẹ̀lú àwọn ibi ìjẹko rẹ̀ ní agbègbè olókè Éfúrémù, Gésérì+ pẹ̀lú àwọn ibi ìjẹko rẹ̀, 22 Kíbúsáímù pẹ̀lú àwọn ibi ìjẹko rẹ̀ àti Bẹti-hórónì+ pẹ̀lú àwọn ibi ìjẹko rẹ̀, ó jẹ́ ìlú mẹ́rin.

23 Látinú ìpín ẹ̀yà Dánì: Élítékè pẹ̀lú àwọn ibi ìjẹko rẹ̀, Gíbétónì pẹ̀lú àwọn ibi ìjẹko rẹ̀, 24 Áíjálónì+ pẹ̀lú àwọn ibi ìjẹko rẹ̀, Gati-rímónì pẹ̀lú àwọn ibi ìjẹko rẹ̀, ó jẹ́ ìlú mẹ́rin.

25 Látinú ìpín ààbọ̀ ẹ̀yà Mánásè: Táánákì+ pẹ̀lú àwọn ibi ìjẹko rẹ̀ àti Gati-rímónì pẹ̀lú àwọn ibi ìjẹko rẹ̀, ó jẹ́ ìlú méjì.

26 Gbogbo ìlú pẹ̀lú àwọn ibi ìjẹko wọn tí àwọn ìdílé ọmọ Kóhátì tí ó ṣẹ́ kù gbà jẹ́ mẹ́wàá.

27 Látinú ìpín ààbọ̀ ẹ̀yà Mánásè, wọ́n fún àwọn ọmọ Gẹ́ṣónì+ tí wọ́n jẹ́ ìdílé ọmọ Léfì ní ìlú ààbò tí ẹni tó bá pààyàn máa sá lọ, ìyẹn Gólánì+ ní Báṣánì pẹ̀lú àwọn ibi ìjẹko rẹ̀ àti Bééṣítérà pẹ̀lú àwọn ibi ìjẹko rẹ̀, ó jẹ́ ìlú méjì.

28 Látinú ìpín ẹ̀yà Ísákà:+ Kíṣíónì pẹ̀lú àwọn ibi ìjẹko rẹ̀, Dábérátì+ pẹ̀lú àwọn ibi ìjẹko rẹ̀, 29 Jámútì pẹ̀lú àwọn ibi ìjẹko rẹ̀ àti Ẹ́ń-gánímù pẹ̀lú àwọn ibi ìjẹko rẹ̀, ó jẹ́ ìlú mẹ́rin.

30 Látinú ìpín ẹ̀yà Áṣérì:+ Míṣálì pẹ̀lú àwọn ibi ìjẹko rẹ̀, Ábídónì pẹ̀lú àwọn ibi ìjẹko rẹ̀, 31 Hélíkátì+ pẹ̀lú àwọn ibi ìjẹko rẹ̀ àti Réhóbù+ pẹ̀lú àwọn ibi ìjẹko rẹ̀, ó jẹ́ ìlú mẹ́rin.

32 Látinú ìpín ẹ̀yà Náfútálì: ìlú ààbò+ tí ẹni tó bá pààyàn máa sá lọ, ìyẹn Kédéṣì+ ní Gálílì pẹ̀lú àwọn ibi ìjẹko rẹ̀, Hamoti-dórì pẹ̀lú àwọn ibi ìjẹko rẹ̀ àti Kátánì pẹ̀lú àwọn ibi ìjẹko rẹ̀, ó jẹ́ ìlú mẹ́ta.

33 Gbogbo ìlú àwọn ọmọ Gẹ́ṣónì ní ìdílé-ìdílé jẹ́ ìlú mẹ́tàlá (13) pẹ̀lú àwọn ibi ìjẹko wọn.

34 Wọ́n fún ìdílé àwọn ọmọ Mérárì,+ àwọn ọmọ Léfì tó ṣẹ́ kù ní àwọn ìlú yìí látinú ìpín ẹ̀yà Sébúlúnì:+ Jókínéámù+ pẹ̀lú àwọn ibi ìjẹko rẹ̀, Kárítà pẹ̀lú àwọn ibi ìjẹko rẹ̀, 35 Dímúnà pẹ̀lú àwọn ibi ìjẹko rẹ̀ àti Náhálálì+ pẹ̀lú àwọn ibi ìjẹko rẹ̀, ó jẹ́ ìlú mẹ́rin.

36 Látinú ìpín ẹ̀yà Rúbẹ́nì: Bésérì+ pẹ̀lú àwọn ibi ìjẹko rẹ̀, Jáhásì pẹ̀lú àwọn ibi ìjẹko rẹ̀,+ 37 Kédémótì pẹ̀lú àwọn ibi ìjẹko rẹ̀ àti Mẹ́fáátì pẹ̀lú àwọn ibi ìjẹko rẹ̀, ó jẹ́ ìlú mẹ́rin.

38 Látinú ìpín ẹ̀yà Gádì:+ ìlú ààbò tí ẹni tó bá pààyàn máa sá lọ, ìyẹn Rámótì ní Gílíádì+ pẹ̀lú àwọn ibi ìjẹko rẹ̀, Máhánáímù+ pẹ̀lú àwọn ibi ìjẹko rẹ̀, 39 Hẹ́ṣíbónì+ pẹ̀lú àwọn ibi ìjẹko rẹ̀ àti Jásérì+ pẹ̀lú àwọn ibi ìjẹko rẹ̀, ó jẹ́ ìlú mẹ́rin.

40 Gbogbo ìlú tí wọ́n pín fún àwọn ọmọ Mérárì ní ìdílé-ìdílé, àwọn tó ṣẹ́ kù nínú ìdílé àwọn ọmọ Léfì jẹ́ ìlú méjìlá (12).

41 Gbogbo ìlú àwọn ọmọ Léfì láàárín ohun ìní àwọn ọmọ Ísírẹ́lì jẹ́ ìlú méjìdínláàádọ́ta (48) pẹ̀lú àwọn ibi ìjẹko wọn.+ 42 Gbogbo àwọn ìlú yìí ló ní àwọn ibi ìjẹko tó yí wọn ká lọ́kọ̀ọ̀kan, bó ṣe rí ní gbogbo àwọn ìlú yìí nìyẹn.

43 Jèhófà fún Ísírẹ́lì ní gbogbo ilẹ̀ tó búra pé òun máa fún àwọn baba ńlá wọn,+ wọ́n gbà á, wọ́n sì ń gbé inú rẹ̀.+ 44 Bákan náà, Jèhófà fún wọn ní ìsinmi ní gbogbo àyíká wọn, bó ṣe búra fún àwọn baba ńlá wọn,+ ìkankan nínú àwọn ọ̀tá wọn ò sì lè dojú kọ wọ́n.+ Jèhófà fi gbogbo ọ̀tá wọn lé wọn lọ́wọ́.+ 45 Kò sí ìlérí* tí kò ṣẹ nínú gbogbo ìlérí dáadáa tí Jèhófà ṣe fún ilé Ísírẹ́lì; gbogbo rẹ̀ ló ṣẹ pátá.+

Yorùbá Publications (1987-2025)
Jáde
Wọlé
  • Yorùbá
  • Fi Ráńṣẹ́
  • Èyí tí mo fẹ́ràn jù
  • Copyright © 2025 Watch Tower Bible and Tract Society of Pennsylvania
  • Àdéhùn Nípa Lílò
  • Òfin
  • Ètò Nípa Ìsọfúnni Rẹ
  • JW.ORG
  • Wọlé
Fi Ráńṣẹ́