ÀKÁ ÌWÉ ORÍ ÍNTÁNẸ́Ẹ̀TÌ ti Watchtower
ÀKÁ ÌWÉ ORÍ ÍŃTÁNẸ́Ẹ̀TÌ
ti Watchtower
Yorùbá
ọ́
  • ẹ
  • ọ
  • ṣ
  • ń
  • ẹ́
  • ẹ̀
  • ọ́
  • ọ̀
  • BÍBÉLÌ
  • ÌTẸ̀JÁDE
  • ÌPÀDÉ
  • Sáàmù 132
  • Bíbélì Mímọ́ ti Ìtumọ̀ Ayé Tuntun

Kò sí fídíò kankan ní apá yìí.

Má bínú, fídíò yìí kò jáde.

Ohun Tó Wà Nínú Ìwé Sáàmù

      • Ó yan Dáfídì àti Síónì

        • “Má ṣe kọ ẹni àmì òróró rẹ sílẹ̀” (10)

        • Ó gbé ìgbàlà wọ àwọn àlùfáà Síónì (16)

Sáàmù 132:1

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +1Sa 20:1

Sáàmù 132:2

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +2Sa 7:2, 3

Sáàmù 132:3

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +2Sa 5:11

Sáàmù 132:5

Àlàyé ìsàlẹ́ ìwé

  • *

    Tàbí “Àgọ́ ìjọsìn títóbi.”

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +2Sa 7:2; 1Ọb 8:17; 1Kr 15:3, 12; Iṣe 7:45, 46

Sáàmù 132:6

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +1Sa 17:12
  • +1Sa 7:1; 1Kr 13:6

Sáàmù 132:7

Àlàyé ìsàlẹ́ ìwé

  • *

    Tàbí “àgọ́ ìjọsìn rẹ̀ títóbi.”

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +Sm 43:3
  • +1Kr 28:2; Sm 5:7

Sáàmù 132:8

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +Nọ 10:35; 2Sa 6:17
  • +2Kr 6:41, 42

Sáàmù 132:10

Àlàyé ìsàlẹ́ ìwé

  • *

    Ní Héb., “yí ojú ẹni àmì òróró rẹ pa dà.”

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +1Ọb 15:4; 2Ọb 19:34

Sáàmù 132:11

Àlàyé ìsàlẹ́ ìwé

  • *

    Ní Héb., “èso ilé ọmọ.”

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +1Ọb 8:25; Sm 89:3, 4, 20, 36; Ais 9:7; Jer 33:20, 21; Mt 9:27; Lk 1:69; Iṣe 2:30, 31; 13:22, 23

Sáàmù 132:12

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +1Kr 29:19
  • +2Sa 7:12, 16; 1Kr 17:11, 12; Sm 89:20, 29

Atọ́ka

  • Ìwé Ìwádìí

    “Ete aiyeraiye,” ojú ìwé 123-126

Sáàmù 132:13

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +Sm 48:2, 3; 78:68; Heb 12:22
  • +Sm 87:2

Sáàmù 132:14

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +Sm 46:5; Ais 24:23

Sáàmù 132:15

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +Sm 22:26; 147:12, 14

Sáàmù 132:16

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +Sm 149:4
  • +Sm 132:8, 9

Sáàmù 132:17

Àlàyé ìsàlẹ́ ìwé

  • *

    Ní Héb., “kí ìwo Dáfídì yọ.”

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +1Ọb 11:36; 15:4; 2Kr 21:7

Sáàmù 132:18

Àlàyé ìsàlẹ́ ìwé

  • *

    Tàbí “dáyádémà.”

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +Sm 2:6; 72:8; Ais 9:6; Ifi 11:15

Àwọn míì

Sm 132:11Sa 20:1
Sm 132:22Sa 7:2, 3
Sm 132:32Sa 5:11
Sm 132:52Sa 7:2; 1Ọb 8:17; 1Kr 15:3, 12; Iṣe 7:45, 46
Sm 132:61Sa 17:12
Sm 132:61Sa 7:1; 1Kr 13:6
Sm 132:7Sm 43:3
Sm 132:71Kr 28:2; Sm 5:7
Sm 132:8Nọ 10:35; 2Sa 6:17
Sm 132:82Kr 6:41, 42
Sm 132:101Ọb 15:4; 2Ọb 19:34
Sm 132:111Ọb 8:25; Sm 89:3, 4, 20, 36; Ais 9:7; Jer 33:20, 21; Mt 9:27; Lk 1:69; Iṣe 2:30, 31; 13:22, 23
Sm 132:121Kr 29:19
Sm 132:122Sa 7:12, 16; 1Kr 17:11, 12; Sm 89:20, 29
Sm 132:13Sm 48:2, 3; 78:68; Heb 12:22
Sm 132:13Sm 87:2
Sm 132:14Sm 46:5; Ais 24:23
Sm 132:15Sm 22:26; 147:12, 14
Sm 132:16Sm 149:4
Sm 132:16Sm 132:8, 9
Sm 132:171Ọb 11:36; 15:4; 2Kr 21:7
Sm 132:18Sm 2:6; 72:8; Ais 9:6; Ifi 11:15
  • Bíbélì Mímọ́ ti Ìtumọ̀ Ayé Tuntun
  • 1
  • 2
  • 3
  • 4
  • 5
  • 6
  • 7
  • 8
  • 9
  • 10
  • 11
  • 12
  • 13
  • 14
  • 15
  • 16
  • 17
  • 18
Bíbélì Mímọ́ ti Ìtumọ̀ Ayé Tuntun
Sáàmù 132:1-18

Sáàmù

Orin Ìgòkè.

132 Jèhófà, jọ̀wọ́ rántí Dáfídì

Àti gbogbo ìyà tó jẹ;+

2 Bó ṣe búra fún Jèhófà,

Bó ṣe jẹ́jẹ̀ẹ́ fún Alágbára Jékọ́bù pé:+

3 “Mi ò ní wọnú àgọ́ mi, àní ilé mi.+

Mi ò ní dùbúlẹ̀ lórí àga tìmùtìmù mi, àní ibùsùn mi;

4 Mi ò ní jẹ́ kí oorun kun ojú mi,

Mi ò sì ní jẹ́ kí ìpéǹpéjú mi tòògbé

5 Títí màá fi rí àyè kan fún Jèhófà,

Ibùgbé tó dáa* fún Alágbára Jékọ́bù.”+

6 Wò ó! A gbọ́ nípa rẹ̀ ní Éfúrátà;+

A rí i nínú igbó kìjikìji.+

7 Ẹ jẹ́ ká wá sínú ibùgbé rẹ̀;*+

Ká forí balẹ̀ níbi àpótí ìtìsẹ̀ rẹ̀.+

8 Dìde, Jèhófà, wá sí ibi ìsinmi rẹ,+

Ìwọ àti Àpótí agbára rẹ.+

9 Kí àwọn àlùfáà rẹ gbé òdodo wọ̀,

Kí àwọn ẹni ìdúróṣinṣin rẹ sì máa kígbe ayọ̀.

10 Nítorí Dáfídì ìránṣẹ́ rẹ,

Má ṣe kọ ẹni àmì òróró rẹ sílẹ̀.*+

11 Jèhófà ti búra fún Dáfídì,

Ó dájú pé kò ní ṣàìmú ọ̀rọ̀ rẹ̀ ṣẹ pé:

“Ọ̀kan lára ọmọ* rẹ

Ni màá gbé gorí ìtẹ́ rẹ.+

12 Tí àwọn ọmọ rẹ bá pa májẹ̀mú mi mọ́

Àti àwọn ìránnilétí mi tí mo kọ́ wọn,+

Àwọn ọmọ tiwọn náà

Yóò jókòó sórí ìtẹ́ rẹ títí láé.”+

13 Nítorí Jèhófà ti yan Síónì;+

Ó fẹ́ kó jẹ́ ibùgbé rẹ̀, ó ní:+

14 “Ibi ìsinmi mi títí láé nìyí;

Ibí ni màá máa gbé,+ nítorí ohun tí mo fẹ́ nìyẹn.

15 Màá fi ọ̀pọ̀ oúnjẹ kún ibẹ̀;

Màá fi oúnjẹ tẹ́ àwọn aláìní ibẹ̀ lọ́rùn.+

16 Màá gbé ìgbàlà wọ àwọn àlùfáà rẹ̀,+

Àwọn adúróṣinṣin rẹ̀ yóò sì kígbe ayọ̀.+

17 Màá mú kí agbára Dáfídì pọ̀ sí i* níbẹ̀.

Mo ti ṣètò fìtílà fún ẹni àmì òróró mi.+

18 Màá gbé ìtìjú wọ àwọn ọ̀tá rẹ̀,

Àmọ́ adé* orí rẹ̀ yóò máa gbilẹ̀.”+

Yorùbá Publications (1987-2025)
Jáde
Wọlé
  • Yorùbá
  • Fi Ráńṣẹ́
  • Èyí tí mo fẹ́ràn jù
  • Copyright © 2025 Watch Tower Bible and Tract Society of Pennsylvania
  • Àdéhùn Nípa Lílò
  • Òfin
  • Ètò Nípa Ìsọfúnni Rẹ
  • JW.ORG
  • Wọlé
Fi Ráńṣẹ́