ÀKÁ ÌWÉ ORÍ ÍNTÁNẸ́Ẹ̀TÌ ti Watchtower
ÀKÁ ÌWÉ ORÍ ÍŃTÁNẸ́Ẹ̀TÌ
ti Watchtower
Yorùbá
ọ́
  • ẹ
  • ọ
  • ṣ
  • ń
  • ẹ́
  • ẹ̀
  • ọ́
  • ọ̀
  • BÍBÉLÌ
  • ÌTẸ̀JÁDE
  • ÌPÀDÉ
  • 1 Kíróníkà 6
  • Bíbélì Mímọ́ ti Ìtumọ̀ Ayé Tuntun

Kò sí fídíò kankan ní apá yìí.

Má bínú, fídíò yìí kò jáde.

Ohun Tó Wà Nínú Ìwé 1 Kíróníkà

      • Àwọn àtọmọdọ́mọ Léfì (1-30)

      • Àwọn akọrin inú tẹ́ńpìlì (31-47)

      • Àwọn àtọmọdọ́mọ Áárónì (48-53)

      • Àwọn ibi tí àwọn ọmọ Léfì gbé (54-81)

1 Kíróníkà 6:1

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +Jẹ 29:34; Ẹk 6:16
  • +Ẹk 6:18; Nọ 3:27
  • +Nọ 3:17; 26:57

1 Kíróníkà 6:2

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +Ẹk 6:21
  • +Ẹk 6:22; Le 10:4

1 Kíróníkà 6:3

Àlàyé ìsàlẹ́ ìwé

  • *

    Ní Héb., “ọmọkùnrin.”

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +Ẹk 6:20
  • +1Kr 23:13
  • +Ẹk 6:26; Iṣe 7:37, 38
  • +Ẹk 15:20
  • +Ẹk 24:1; Le 10:1
  • +Nọ 3:32; Di 10:6
  • +Ẹk 6:23; 28:1; Nọ 4:28; 1Kr 24:2, 4

1 Kíróníkà 6:4

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +Ẹk 6:25; Nọ 25:11

1 Kíróníkà 6:7

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +2Sa 8:17

1 Kíróníkà 6:8

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +1Ọb 1:8; 2:35
  • +2Sa 15:27, 36

1 Kíróníkà 6:12

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +Ne 11:11

1 Kíróníkà 6:13

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +2Kr 34:14

1 Kíróníkà 6:14

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +2Ọb 25:18
  • +Hag 1:1

1 Kíróníkà 6:16

Àlàyé ìsàlẹ́ ìwé

  • *

    Wọ́n tún pè é ní Gẹ́ṣónì ní ẹsẹ 1.

1 Kíróníkà 6:17

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +Nọ 3:18

1 Kíróníkà 6:18

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +Nọ 3:19, 20

1 Kíróníkà 6:19

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +Nọ 26:57

1 Kíróníkà 6:20

Àlàyé ìsàlẹ́ ìwé

  • *

    Ọ̀rọ̀ yìí ní Hébérù lè túmọ̀ sí ọmọ, ọmọ ọmọ tàbí àtọmọdọ́mọ.

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +Nọ 3:18

1 Kíróníkà 6:22

Àlàyé ìsàlẹ́ ìwé

  • *

    Tàbí “Àtọmọdọ́mọ.”

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +Nọ 16:1, 32; 26:10, 11; Jud 11

1 Kíróníkà 6:23

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +Ẹk 6:24

1 Kíróníkà 6:27

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +1Sa 1:1

1 Kíróníkà 6:28

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +1Sa 1:20
  • +1Sa 8:1, 2

1 Kíróníkà 6:29

Àlàyé ìsàlẹ́ ìwé

  • *

    Tàbí “Àtọmọdọ́mọ.”

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +Ẹk 6:19; 1Kr 23:21

1 Kíróníkà 6:31

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +2Sa 6:17; 1Kr 15:16

1 Kíróníkà 6:32

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +1Ọb 6:14
  • +2Kr 35:15

1 Kíróníkà 6:33

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +1Kr 15:16, 17
  • +1Sa 8:1, 2

1 Kíróníkà 6:34

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +1Sa 1:1

1 Kíróníkà 6:39

Àlàyé ìsàlẹ́ ìwé

  • *

    Ìyẹn, “ọmọ Léfì bíi tiẹ̀.”

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +1Kr 25:1; 2Kr 5:12; Sm 50:àkọlé

1 Kíróníkà 6:44

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +1Kr 23:6
  • +1Kr 15:16, 17

1 Kíróníkà 6:48

Àlàyé ìsàlẹ́ ìwé

  • *

    Ní Héb., “ni a fi lélẹ̀.”

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +Nọ 3:5-7

1 Kíróníkà 6:49

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +Ẹk 28:1; Nọ 3:10
  • +Ẹk 29:38
  • +Ẹk 30:7
  • +Ẹk 30:10; Le 4:20; 17:11; 2Kr 29:24

1 Kíróníkà 6:50

Àlàyé ìsàlẹ́ ìwé

  • *

    Ọ̀rọ̀ yìí ní Hébérù lè túmọ̀ sí ọmọ, ọmọ ọmọ tàbí àtọmọdọ́mọ.

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +Ẹk 6:23
  • +Ẹk 28:1; Nọ 3:32

1 Kíróníkà 6:52

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +2Sa 8:17

1 Kíróníkà 6:53

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +1Ọb 2:35

1 Kíróníkà 6:54

Àlàyé ìsàlẹ́ ìwé

  • *

    Tàbí “àgọ́ olódi.”

1 Kíróníkà 6:55

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +Nọ 13:22; Joṣ 21:8, 11

1 Kíróníkà 6:56

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +Joṣ 14:13; Ond 1:20

1 Kíróníkà 6:57

Àlàyé ìsàlẹ́ ìwé

  • *

    Tàbí kó jẹ́, “ìlú,” èyí bá Joṣ 21:13 mu.

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +Nọ 35:12, 13
  • +Joṣ 20:7, 9
  • +Joṣ 15:20, 42
  • +Joṣ 15:20, 48
  • +Joṣ 21:13-16

1 Kíróníkà 6:58

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +Ond 1:11

1 Kíróníkà 6:59

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +1Kr 4:24, 32
  • +Joṣ 15:10, 12

1 Kíróníkà 6:60

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +Joṣ 18:21, 24
  • +Joṣ 21:8, 18; Jer 1:1
  • +Joṣ 21:4

1 Kíróníkà 6:61

Àlàyé ìsàlẹ́ ìwé

  • *

    Tàbí “ṣẹ́ kèké láti fún.”

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +Joṣ 21:5

1 Kíróníkà 6:62

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +Joṣ 21:27-33

1 Kíróníkà 6:63

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +Joṣ 21:34-40

1 Kíróníkà 6:64

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +Nọ 35:2-4

1 Kíróníkà 6:66

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +Joṣ 21:20-26

1 Kíróníkà 6:67

Àlàyé ìsàlẹ́ ìwé

  • *

    Tàbí kó jẹ́, “ìlú,” èyí bá Joṣ 21:21 mu.

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +Joṣ 20:7, 9
  • +Joṣ 16:10

1 Kíróníkà 6:68

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +Joṣ 10:11

1 Kíróníkà 6:69

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +Joṣ 10:12; Ond 1:35
  • +Joṣ 19:45, 48

1 Kíróníkà 6:71

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +Di 4:41-43
  • +Joṣ 21:27

1 Kíróníkà 6:72

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +Joṣ 19:12, 16
  • +Joṣ 21:8, 28

1 Kíróníkà 6:74

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +Joṣ 21:8, 30

1 Kíróníkà 6:75

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +Joṣ 19:28, 31; Ond 1:31

1 Kíróníkà 6:76

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +Joṣ 20:7, 9; 21:32, 33
  • +Mt 3:13

1 Kíróníkà 6:77

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +Joṣ 21:34-39

1 Kíróníkà 6:78

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +Nọ 21:23

1 Kíróníkà 6:79

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +Di 2:26

1 Kíróníkà 6:80

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +Jẹ 32:1, 2; 2Sa 2:8

1 Kíróníkà 6:81

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +Nọ 21:26
  • +Nọ 32:1

Àwọn míì

1 Kíró. 6:1Jẹ 29:34; Ẹk 6:16
1 Kíró. 6:1Ẹk 6:18; Nọ 3:27
1 Kíró. 6:1Nọ 3:17; 26:57
1 Kíró. 6:2Ẹk 6:21
1 Kíró. 6:2Ẹk 6:22; Le 10:4
1 Kíró. 6:3Ẹk 6:20
1 Kíró. 6:31Kr 23:13
1 Kíró. 6:3Ẹk 6:26; Iṣe 7:37, 38
1 Kíró. 6:3Ẹk 15:20
1 Kíró. 6:3Ẹk 24:1; Le 10:1
1 Kíró. 6:3Nọ 3:32; Di 10:6
1 Kíró. 6:3Ẹk 6:23; 28:1; Nọ 4:28; 1Kr 24:2, 4
1 Kíró. 6:4Ẹk 6:25; Nọ 25:11
1 Kíró. 6:72Sa 8:17
1 Kíró. 6:81Ọb 1:8; 2:35
1 Kíró. 6:82Sa 15:27, 36
1 Kíró. 6:12Ne 11:11
1 Kíró. 6:132Kr 34:14
1 Kíró. 6:142Ọb 25:18
1 Kíró. 6:14Hag 1:1
1 Kíró. 6:17Nọ 3:18
1 Kíró. 6:18Nọ 3:19, 20
1 Kíró. 6:19Nọ 26:57
1 Kíró. 6:20Nọ 3:18
1 Kíró. 6:22Nọ 16:1, 32; 26:10, 11; Jud 11
1 Kíró. 6:23Ẹk 6:24
1 Kíró. 6:271Sa 1:1
1 Kíró. 6:281Sa 1:20
1 Kíró. 6:281Sa 8:1, 2
1 Kíró. 6:29Ẹk 6:19; 1Kr 23:21
1 Kíró. 6:312Sa 6:17; 1Kr 15:16
1 Kíró. 6:321Ọb 6:14
1 Kíró. 6:322Kr 35:15
1 Kíró. 6:331Kr 15:16, 17
1 Kíró. 6:331Sa 8:1, 2
1 Kíró. 6:341Sa 1:1
1 Kíró. 6:391Kr 25:1; 2Kr 5:12; Sm 50:àkọlé
1 Kíró. 6:441Kr 23:6
1 Kíró. 6:441Kr 15:16, 17
1 Kíró. 6:48Nọ 3:5-7
1 Kíró. 6:49Ẹk 28:1; Nọ 3:10
1 Kíró. 6:49Ẹk 29:38
1 Kíró. 6:49Ẹk 30:7
1 Kíró. 6:49Ẹk 30:10; Le 4:20; 17:11; 2Kr 29:24
1 Kíró. 6:50Ẹk 6:23
1 Kíró. 6:50Ẹk 28:1; Nọ 3:32
1 Kíró. 6:522Sa 8:17
1 Kíró. 6:531Ọb 2:35
1 Kíró. 6:55Nọ 13:22; Joṣ 21:8, 11
1 Kíró. 6:56Joṣ 14:13; Ond 1:20
1 Kíró. 6:57Nọ 35:12, 13
1 Kíró. 6:57Joṣ 20:7, 9
1 Kíró. 6:57Joṣ 15:20, 42
1 Kíró. 6:57Joṣ 15:20, 48
1 Kíró. 6:57Joṣ 21:13-16
1 Kíró. 6:58Ond 1:11
1 Kíró. 6:591Kr 4:24, 32
1 Kíró. 6:59Joṣ 15:10, 12
1 Kíró. 6:60Joṣ 18:21, 24
1 Kíró. 6:60Joṣ 21:8, 18; Jer 1:1
1 Kíró. 6:60Joṣ 21:4
1 Kíró. 6:61Joṣ 21:5
1 Kíró. 6:62Joṣ 21:27-33
1 Kíró. 6:63Joṣ 21:34-40
1 Kíró. 6:64Nọ 35:2-4
1 Kíró. 6:66Joṣ 21:20-26
1 Kíró. 6:67Joṣ 20:7, 9
1 Kíró. 6:67Joṣ 16:10
1 Kíró. 6:68Joṣ 10:11
1 Kíró. 6:69Joṣ 10:12; Ond 1:35
1 Kíró. 6:69Joṣ 19:45, 48
1 Kíró. 6:71Di 4:41-43
1 Kíró. 6:71Joṣ 21:27
1 Kíró. 6:72Joṣ 19:12, 16
1 Kíró. 6:72Joṣ 21:8, 28
1 Kíró. 6:74Joṣ 21:8, 30
1 Kíró. 6:75Joṣ 19:28, 31; Ond 1:31
1 Kíró. 6:76Joṣ 20:7, 9; 21:32, 33
1 Kíró. 6:76Mt 3:13
1 Kíró. 6:77Joṣ 21:34-39
1 Kíró. 6:78Nọ 21:23
1 Kíró. 6:79Di 2:26
1 Kíró. 6:80Jẹ 32:1, 2; 2Sa 2:8
1 Kíró. 6:81Nọ 21:26
1 Kíró. 6:81Nọ 32:1
  • Bíbélì Mímọ́ ti Ìtumọ̀ Ayé Tuntun
  • 1
  • 2
  • 3
  • 4
  • 5
  • 6
  • 7
  • 8
  • 9
  • 10
  • 11
  • 12
  • 13
  • 14
  • 15
  • 16
  • 17
  • 18
  • 19
  • 20
  • 21
  • 22
  • 23
  • 24
  • 25
  • 26
  • 27
  • 28
  • 29
  • 30
  • 31
  • 32
  • 33
  • 34
  • 35
  • 36
  • 37
  • 38
  • 39
  • 40
  • 41
  • 42
  • 43
  • 44
  • 45
  • 46
  • 47
  • 48
  • 49
  • 50
  • 51
  • 52
  • 53
  • 54
  • 55
  • 56
  • 57
  • 58
  • 59
  • 60
  • 61
  • 62
  • 63
  • 64
  • 65
  • 66
  • 67
  • 68
  • 69
  • 70
  • 71
  • 72
  • 73
  • 74
  • 75
  • 76
  • 77
  • 78
  • 79
  • 80
  • 81
Bíbélì Mímọ́ ti Ìtumọ̀ Ayé Tuntun
1 Kíróníkà 6:1-81

Kíróníkà Kìíní

6 Àwọn ọmọ Léfì+ ni Gẹ́ṣónì, Kóhátì+ àti Mérárì.+ 2 Àwọn ọmọ Kóhátì ni Ámúrámù, Ísárì,+ Hébúrónì àti Úsíélì.+ 3 Àwọn ọmọ* Ámúrámù+ ni Áárónì,+ Mósè+ àti Míríámù.+ Àwọn ọmọ Áárónì sì ni Nádábù, Ábíhù,+ Élíásárì+ àti Ítámárì.+ 4 Élíásárì bí Fíníhásì;+ Fíníhásì bí Ábíṣúà. 5 Ábíṣúà bí Búkì; Búkì bí Úsáì. 6 Úsáì bí Seraháyà; Seraháyà bí Méráótì. 7 Méráótì bí Amaráyà; Amaráyà bí Áhítúbù.+ 8 Áhítúbù bí Sádókù;+ Sádókù bí Áhímáásì.+ 9 Áhímáásì bí Asaráyà; Asaráyà bí Jóhánánì. 10 Jóhánánì bí Asaráyà. Ó ṣe iṣẹ́ àlùfáà ní ilé tí Sólómọ́nì kọ́ sí Jerúsálẹ́mù.

11 Asaráyà bí Amaráyà; Amaráyà bí Áhítúbù. 12 Áhítúbù bí Sádókù;+ Sádókù bí Ṣálúmù. 13 Ṣálúmù bí Hilikáyà;+ Hilikáyà bí Asaráyà. 14 Asaráyà bí Seráyà;+ Seráyà bí Jèhósádákì.+ 15 Jèhósádákì lọ sí ìgbèkùn nígbà tí Jèhófà mú kí Nebukadinésárì kó Júdà àti Jerúsálẹ́mù lọ sí ìgbèkùn.

16 Àwọn ọmọ Léfì ni Gẹ́ṣómù,* Kóhátì àti Mérárì. 17 Orúkọ àwọn ọmọ Gẹ́ṣómù nìyí: Líbínì àti Ṣíméì.+ 18 Àwọn ọmọ Kóhátì ni Ámúrámù, Ísárì, Hébúrónì àti Úsíélì.+ 19 Àwọn ọmọ Mérárì ni Máhílì àti Múṣì.

Ìdílé àwọn baba ńlá àwọn ọmọ Léfì+ nìwọ̀nyí: 20 Ní ti Gẹ́ṣómù,+ ọmọ* rẹ̀ ni Líbínì, ọmọ rẹ̀ ni Jáhátì, ọmọ rẹ̀ ni Símà, 21 ọmọ rẹ̀ ni Jóà, ọmọ rẹ̀ ni Ídò, ọmọ rẹ̀ ni Síírà, ọmọ rẹ̀ sì ni Jéátéráì. 22 Àwọn ọmọ* Kóhátì ni Ámínádábù, ọmọ rẹ̀ ni Kórà,+ ọmọ rẹ̀ ni Ásírì, 23 ọmọ rẹ̀ ni Ẹlikénà, ọmọ rẹ̀ ni Ébíásáfù,+ ọmọ rẹ̀ ni Ásírì, 24 ọmọ rẹ̀ ni Táhátì, ọmọ rẹ̀ ni Úríélì, ọmọ rẹ̀ ni Ùsáyà, ọmọ rẹ̀ sì ni Ṣéọ́lù. 25 Àwọn ọmọ Ẹlikénà ni Ámásáì àti Áhímótì. 26 Ní ti Ẹlikénà, àwọn ọmọ Ẹlikénà ni Sófáì, ọmọ rẹ̀ ni Náhátì, 27 ọmọ rẹ̀ ni Élíábù, ọmọ rẹ̀ ni Jéróhámù, ọmọ rẹ̀ ni Ẹlikénà.+ 28 Àwọn ọmọ Sámúẹ́lì+ ni Jóẹ́lì àkọ́bí àti ìkejì Ábíjà.+ 29 Àwọn ọmọ* Mérárì ni Máhílì,+ ọmọ rẹ̀ ni Líbínì, ọmọ rẹ̀ ni Ṣíméì, ọmọ rẹ̀ ni Úsà, 30 ọmọ rẹ̀ ni Ṣíméà, ọmọ rẹ̀ ni Hagáyà, ọmọ rẹ̀ sì ni Ásáyà.

31 Àwọn tí Dáfídì yàn pé kí wọ́n máa darí orin ní ilé Jèhófà lẹ́yìn tí wọ́n gbé Àpótí náà síbẹ̀ nìyí.+ 32 Ojúṣe wọn ni láti máa kọrin ní àgọ́ ìjọsìn, ìyẹn ni àgọ́ ìpàdé títí di ìgbà tí Sólómọ́nì kọ́ ilé Jèhófà ní Jerúsálẹ́mù,+ wọ́n sì ń ṣe iṣẹ́ tí wọ́n yàn fún wọn bí wọ́n ṣe ni kí wọ́n máa ṣe é.+ 33 Àwọn tó ṣiṣẹ́ pẹ̀lú àwọn ọmọ wọn nìyí: Látinú àwọn ọmọ Kóhátì, Hémánì+ akọrin, ọmọ Jóẹ́lì,+ ọmọ Sámúẹ́lì, 34 ọmọ Ẹlikénà,+ ọmọ Jéróhámù, ọmọ Élíélì, ọmọ Tóà, 35 ọmọ Súfì, ọmọ Ẹlikénà, ọmọ Máhátì, ọmọ Ámásáì, 36 ọmọ Ẹlikénà, ọmọ Jóẹ́lì, ọmọ Asaráyà, ọmọ Sefanáyà, 37 ọmọ Táhátì, ọmọ Ásírì, ọmọ Ébíásáfù, ọmọ Kórà, 38 ọmọ Ísárì, ọmọ Kóhátì, ọmọ Léfì, ọmọ Ísírẹ́lì.

39 Ásáfù+ arákùnrin rẹ̀* dúró ní apá ọ̀tún Hémánì; Ásáfù jẹ́ ọmọ Berekáyà, ọmọ Ṣíméà, 40 ọmọ Máíkẹ́lì, ọmọ Baaseáyà, ọmọ Málíkíjà, 41 ọmọ Étínì, ọmọ Síírà, ọmọ Ádáyà, 42 ọmọ Étánì, ọmọ Símà, ọmọ Ṣíméì, 43 ọmọ Jáhátì, ọmọ Gẹ́ṣómù, ọmọ Léfì.

44 Àwọn ọmọ Mérárì+ arákùnrin wọn wà ní apá òsì; ibẹ̀ ni Étánì+ wà, ọmọ Kííṣì, ọmọ Ábídì, ọmọ Málúkù, 45 ọmọ Haṣabáyà, ọmọ Amasááyà, ọmọ Hilikáyà, 46 ọmọ Ámísì, ọmọ Bánì, ọmọ Ṣémérì, 47 ọmọ Máhílì, ọmọ Múṣì, ọmọ Mérárì, ọmọ Léfì.

48 Àwọn arákùnrin wọn, àwọn ọmọ Léfì ni a yàn* láti máa ṣe gbogbo iṣẹ́ àgọ́ ìjọsìn, ìyẹn ilé Ọlọ́run tòótọ́.+ 49 Áárónì àti àwọn ọmọ rẹ̀+ mú ẹbọ rú èéfín lórí pẹpẹ ẹbọ sísun+ àti lórí pẹpẹ tùràrí,+ wọ́n ń ṣe àwọn iṣẹ́ tó jẹ mọ́ àwọn ohun mímọ́ jù lọ, láti ṣe ètùtù fún Ísírẹ́lì,+ gẹ́gẹ́ bí gbogbo ohun tí Mósè ìránṣẹ́ Ọlọ́run tòótọ́ pa láṣẹ. 50 Àwọn àtọmọdọ́mọ Áárónì+ nìyí: ọmọ* rẹ̀ ni Élíásárì,+ ọmọ rẹ̀ ni Fíníhásì, ọmọ rẹ̀ ni Ábíṣúà, 51 ọmọ rẹ̀ ni Búkì, ọmọ rẹ̀ ni Úsáì, ọmọ rẹ̀ ni Seraháyà, 52 ọmọ rẹ̀ ni Méráótì, ọmọ rẹ̀ ni Amaráyà, ọmọ rẹ̀ ni Áhítúbù,+ 53 ọmọ rẹ̀ ni Sádókù,+ ọmọ rẹ̀ ni Áhímáásì.

54 Bí a ṣe ṣètò wọn sí ibùdó wọn* ní ìpínlẹ̀ tí wọ́n ń gbé nìyí: fún àwọn ọmọ Áárónì tí wọ́n jẹ́ ti ìdílé àwọn ọmọ Kóhátì, nítorí ọwọ́ wọn ni ìpín àkọ́kọ́ bọ́ sí, 55 wọ́n fún wọn ní Hébúrónì+ ní ilẹ̀ Júdà pẹ̀lú àwọn ibi ìjẹko tó yí i ká. 56 Àmọ́ Kélẹ́bù+ ọmọ Jéfúnè ni wọ́n fún ní pápá tó wà ní ìlú náà àti àwọn ìletò rẹ̀. 57 Àwọn ọmọ Áárónì ni wọ́n fún ní àwọn ìlú* ààbò,+ Hébúrónì+ àti Líbínà+ pẹ̀lú àwọn ibi ìjẹko rẹ̀ àti Játírì+ àti Éṣítémóà pẹ̀lú àwọn ìgbèríko rẹ̀,+ 58 Hílénì pẹ̀lú àwọn ibi ìjẹko rẹ̀, Débírì+ pẹ̀lú àwọn ibi ìjẹko rẹ̀, 59 Áṣánì+ pẹ̀lú àwọn ibi ìjẹko rẹ̀ àti Bẹti-ṣémẹ́ṣì  + pẹ̀lú àwọn ibi ìjẹko rẹ̀; 60 láti inú ẹ̀yà Bẹ́ńjámínì, Gébà+ pẹ̀lú àwọn ibi ìjẹko rẹ̀, Álémétì pẹ̀lú àwọn ibi ìjẹko rẹ̀ àti Ánátótì+ pẹ̀lú àwọn ibi ìjẹko rẹ̀. Gbogbo ìlú tí wọ́n fún ìdílé wọn jẹ́ mẹ́tàlá (13).+

61 Wọ́n fún* àwọn ọmọ Kóhátì tó ṣẹ́ kù ní ìlú mẹ́wàá, látinú ìdílé ẹ̀yà náà, látinú ààbọ̀ ẹ̀yà náà, ààbọ̀ Mánásè.+

62 Wọ́n fún àwọn ọmọ Gẹ́ṣómù àti àwọn ìdílé wọn ní ìlú mẹ́tàlá (13) látinú ẹ̀yà Ísákà, ẹ̀yà Áṣérì, ẹ̀yà Náfútálì àti ẹ̀yà Mánásè ní Báṣánì.+

63 Wọ́n ṣẹ́ kèké, wọ́n sì fún àwọn ọmọ Mérárì àti àwọn ìdílé wọn ní ìlú méjìlá (12) látinú ẹ̀yà Rúbẹ́nì, ẹ̀yà Gádì àti ẹ̀yà Sébúlúnì.+

64 Bí àwọn ọmọ Ísírẹ́lì ṣe fún àwọn ọmọ Léfì ní àwọn ìlú yìí pẹ̀lú àwọn ibi ìjẹko+ wọn nìyẹn. 65 Síwájú sí i, wọ́n ṣẹ́ kèké, wọ́n sì pín àwọn ìlú tí a dárúkọ yìí, èyí tí wọ́n gbà látinú ẹ̀yà Júdà, ẹ̀yà Síméónì àti ẹ̀yà Bẹ́ńjámínì.

66 Àwọn kan lára ìdílé àwọn ọmọ Kóhátì gba àwọn ìlú látinú ẹ̀yà Éfúrémù láti fi ṣe ìpínlẹ̀ wọn.+ 67 Wọ́n fún wọn ní àwọn ìlú* ààbò, Ṣékémù+ pẹ̀lú àwọn ibi ìjẹko rẹ̀ ní agbègbè olókè Éfúrémù, Gésérì+ pẹ̀lú àwọn ibi ìjẹko rẹ̀, 68 Jókíméámù pẹ̀lú àwọn ibi ìjẹko rẹ̀, Bẹti-hórónì+ pẹ̀lú àwọn ibi ìjẹko rẹ̀, 69 Áíjálónì+ pẹ̀lú àwọn ibi ìjẹko rẹ̀ àti Gati-rímónì+ pẹ̀lú àwọn ibi ìjẹko rẹ̀; 70 látinú ààbọ̀ ẹ̀yà Mánásè, a fún ìdílé àwọn ọmọ Kóhátì tí ó ṣẹ́ kù ní Ánérì pẹ̀lú àwọn ibi ìjẹko rẹ̀ àti Bíléámù pẹ̀lú àwọn ibi ìjẹko rẹ̀.

71 Látinú ìdílé ààbọ̀ ẹ̀yà Mánásè, wọ́n fún àwọn ọmọ Gẹ́ṣómù ní Gólánì+ tó wà ní Báṣánì pẹ̀lú àwọn ibi ìjẹko rẹ̀ àti Áṣítárótì pẹ̀lú àwọn ibi ìjẹko rẹ̀;+ 72 látinú ẹ̀yà Ísákà, Kédéṣì pẹ̀lú àwọn ibi ìjẹko rẹ̀, Dábérátì+ pẹ̀lú àwọn ibi ìjẹko rẹ̀,+ 73 Rámótì pẹ̀lú àwọn ibi ìjẹko rẹ̀ àti Ánémù pẹ̀lú àwọn ibi ìjẹko rẹ̀; 74 látinú ẹ̀yà Áṣérì, Máṣálì pẹ̀lú àwọn ibi ìjẹko rẹ̀ àti Ábídónì pẹ̀lú àwọn ibi ìjẹko rẹ̀,+ 75 Húkọ́kù pẹ̀lú àwọn ibi ìjẹko rẹ̀ àti Réhóbù+ pẹ̀lú àwọn ibi ìjẹko rẹ̀; 76 látinú ẹ̀yà Náfútálì, Kédéṣì+ ní Gálílì+ pẹ̀lú àwọn ibi ìjẹko rẹ̀, Hámónì pẹ̀lú àwọn ibi ìjẹko rẹ̀ àti Kíríátáímù pẹ̀lú àwọn ibi ìjẹko rẹ̀.

77 Látinú ẹ̀yà Sébúlúnì,+ wọ́n fún àwọn ọmọ Mérárì tó ṣẹ́ kù ní Rímónò pẹ̀lú àwọn ibi ìjẹko rẹ̀ àti Tábórì pẹ̀lú àwọn ibi ìjẹko rẹ̀; 78 láti ara ilẹ̀ ẹ̀yà Rúbẹ́nì tó wà ní agbègbè ilẹ̀ Jọ́dánì ní Jẹ́ríkò títí dé apá ìlà oòrùn Jọ́dánì, wọ́n fún wọn ní Bésérì tó wà ní aginjù pẹ̀lú àwọn ibi ìjẹko rẹ̀, Jáhásì+ pẹ̀lú àwọn ibi ìjẹko rẹ̀, 79 Kédémótì+ pẹ̀lú àwọn ibi ìjẹko rẹ̀ àti Mẹ́fáátì pẹ̀lú àwọn ibi ìjẹko rẹ̀; 80 látinú ẹ̀yà Gádì, Rámótì ní Gílíádì pẹ̀lú àwọn ibi ìjẹko rẹ̀, Máhánáímù+ pẹ̀lú àwọn ibi ìjẹko rẹ̀, 81 Hẹ́ṣíbónì+ pẹ̀lú àwọn ibi ìjẹko rẹ̀ àti Jásérì+ pẹ̀lú àwọn ibi ìjẹko rẹ̀.

Yorùbá Publications (1987-2025)
Jáde
Wọlé
  • Yorùbá
  • Fi Ráńṣẹ́
  • Èyí tí mo fẹ́ràn jù
  • Copyright © 2025 Watch Tower Bible and Tract Society of Pennsylvania
  • Àdéhùn Nípa Lílò
  • Òfin
  • Ètò Nípa Ìsọfúnni Rẹ
  • JW.ORG
  • Wọlé
Fi Ráńṣẹ́