ÀKÁ ÌWÉ ORÍ ÍNTÁNẸ́Ẹ̀TÌ ti Watchtower
ÀKÁ ÌWÉ ORÍ ÍŃTÁNẸ́Ẹ̀TÌ
ti Watchtower
Yorùbá
ọ́
  • ẹ
  • ọ
  • ṣ
  • ń
  • ẹ́
  • ẹ̀
  • ọ́
  • ọ̀
  • BÍBÉLÌ
  • ÌTẸ̀JÁDE
  • ÌPÀDÉ
  • Diutarónómì 33
  • Bíbélì Mímọ́ ti Ìtumọ̀ Ayé Tuntun

Kò sí fídíò kankan ní apá yìí.

Má bínú, fídíò yìí kò jáde.

Ohun Tó Wà Nínú Ìwé Diutarónómì

      • Mósè súre fún àwọn ẹ̀yà wọn (1-29)

        • “Ọwọ́ ayérayé” Jèhófà (27)

Diutarónómì 33:1

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +Jẹ 49:28

Diutarónómì 33:2

Àlàyé ìsàlẹ́ ìwé

  • *

    Tàbí “ẹgbẹẹgbàárùn-ún.”

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +Ẹk 19:18
  • +Hab 3:3
  • +Da 7:10; Jud 14
  • +Sm 68:17

Diutarónómì 33:3

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +Di 7:8; Ho 11:1
  • +Ẹk 19:6
  • +Ẹk 19:23
  • +Ẹk 20:19

Diutarónómì 33:4

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +Ẹk 24:8
  • +Di 4:8; Iṣe 7:53

Diutarónómì 33:5

Àlàyé ìsàlẹ́ ìwé

  • *

    Ó túmọ̀ sí “Adúróṣinṣin,” orúkọ oyè tí wọ́n fún Ísírẹ́lì.

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +Ais 44:2
  • +Ẹk 18:25; 19:7
  • +Nọ 1:44, 46

Atọ́ka

  • Ìwé Ìwádìí

    “Ete aiyeraiye,” ojú ìwé 115-116

Diutarónómì 33:6

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +Jẹ 49:3
  • +Nọ 26:7; Joṣ 13:15

Diutarónómì 33:7

Àlàyé ìsàlẹ́ ìwé

  • *

    Tàbí “jà fún.”

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +Jẹ 49:8; 1Kr 5:2
  • +Sm 78:68
  • +Ond 1:2; 2Sa 7:8, 9

Diutarónómì 33:8

Àlàyé ìsàlẹ́ ìwé

  • *

    Nínú ẹsẹ yìí, “rẹ” àti “ọ” ń tọ́ka sí Ọlọ́run.

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +Jẹ 49:5; Nọ 3:12
  • +Ẹk 28:30; Le 8:6, 8
  • +Ẹk 32:26
  • +Ẹk 17:7
  • +Nọ 20:13

Diutarónómì 33:9

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +Ẹk 32:27; Le 10:6, 7
  • +Mal 2:4, 5

Diutarónómì 33:10

Àlàyé ìsàlẹ́ ìwé

  • *

    Ní Héb., “sínú imú rẹ.”

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +Di 17:9
  • +2Kr 17:8, 9; Mal 2:7
  • +Ẹk 30:7; Nọ 16:40
  • +Le 1:9

Diutarónómì 33:11

Àlàyé ìsàlẹ́ ìwé

  • *

    Tàbí “ìbàdí.”

Diutarónómì 33:12

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +Jẹ 49:27

Diutarónómì 33:13

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +Jẹ 49:22
  • +Joṣ 16:1
  • +Jẹ 49:25

Diutarónómì 33:14

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +Le 26:5; Sm 65:9

Diutarónómì 33:15

Àlàyé ìsàlẹ́ ìwé

  • *

    Tàbí kó jẹ́, “àwọn òkè ìlà oòrùn.”

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +Joṣ 17:17, 18

Diutarónómì 33:16

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +Di 8:7, 8
  • +Ẹk 3:4; Iṣe 7:30
  • +Jẹ 37:7; 49:26; 1Kr 5:1, 2

Diutarónómì 33:17

Àlàyé ìsàlẹ́ ìwé

  • *

    Tàbí “kan.”

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +Jẹ 48:19, 20

Diutarónómì 33:18

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +Jẹ 49:13
  • +Jẹ 49:14

Diutarónómì 33:19

Àlàyé ìsàlẹ́ ìwé

  • *

    Ní Héb., “fa ọ̀pọ̀ rẹpẹtẹ ohun tó wà nínú.”

  • *

    Tàbí “ìṣúra.”

Diutarónómì 33:20

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +Jẹ 49:19
  • +Joṣ 13:24-28

Diutarónómì 33:21

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +Nọ 32:1-5
  • +Joṣ 22:1, 4

Diutarónómì 33:22

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +Jẹ 49:16
  • +Ond 13:2, 24; 15:8, 20; 16:30
  • +Joṣ 19:47

Diutarónómì 33:23

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +Jẹ 49:21

Diutarónómì 33:24

Àlàyé ìsàlẹ́ ìwé

  • *

    Tàbí “wẹ ẹsẹ̀ rẹ̀ nínú òróró.”

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +Jẹ 49:20

Diutarónómì 33:25

Àlàyé ìsàlẹ́ ìwé

  • *

    Ní Héb., “Agbára rẹ yóò sì rí bí àwọn ọjọ́ rẹ.”

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +Di 8:7, 9

Diutarónómì 33:26

Àlàyé ìsàlẹ́ ìwé

  • *

    Tàbí “ìkùukùu.”

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +Ẹk 15:11
  • +Ais 44:2
  • +Sm 68:32-34

Diutarónómì 33:27

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +Sm 46:11; 91:2
  • +Ais 40:11
  • +Di 9:3
  • +Di 31:3, 4

Atọ́ka

  • Ìwé Ìwádìí

    Ilé Ìṣọ́ (Ẹ̀dà Tó Wà fún Ìkẹ́kọ̀ọ́),

    11/2021, ojú ìwé 6

    Ìwé Ìpàdé Ìgbésí Ayé àti Iṣẹ́ Òjíṣẹ́,

    9/2021, ojú ìwé 2

    Ìjọsìn Mímọ́, ojú ìwé 120

    Ilé-Ìṣọ́nà,

    10/1/1991, ojú ìwé 13

Diutarónómì 33:28

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +Di 8:7, 8
  • +Di 11:11

Diutarónómì 33:29

Àlàyé ìsàlẹ́ ìwé

  • *

    Tàbí kó jẹ́, “àwọn ibi gíga.”

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +Sm 33:12; 144:15; 146:5
  • +Di 4:7; 2Sa 7:23; Sm 147:20
  • +Sm 27:1; Ais 12:2
  • +Sm 115:9
  • +Sm 66:3

Àwọn míì

Diu. 33:1Jẹ 49:28
Diu. 33:2Ẹk 19:18
Diu. 33:2Hab 3:3
Diu. 33:2Da 7:10; Jud 14
Diu. 33:2Sm 68:17
Diu. 33:3Di 7:8; Ho 11:1
Diu. 33:3Ẹk 19:6
Diu. 33:3Ẹk 19:23
Diu. 33:3Ẹk 20:19
Diu. 33:4Ẹk 24:8
Diu. 33:4Di 4:8; Iṣe 7:53
Diu. 33:5Ais 44:2
Diu. 33:5Ẹk 18:25; 19:7
Diu. 33:5Nọ 1:44, 46
Diu. 33:6Jẹ 49:3
Diu. 33:6Nọ 26:7; Joṣ 13:15
Diu. 33:7Jẹ 49:8; 1Kr 5:2
Diu. 33:7Sm 78:68
Diu. 33:7Ond 1:2; 2Sa 7:8, 9
Diu. 33:8Jẹ 49:5; Nọ 3:12
Diu. 33:8Ẹk 28:30; Le 8:6, 8
Diu. 33:8Ẹk 32:26
Diu. 33:8Ẹk 17:7
Diu. 33:8Nọ 20:13
Diu. 33:9Ẹk 32:27; Le 10:6, 7
Diu. 33:9Mal 2:4, 5
Diu. 33:10Di 17:9
Diu. 33:102Kr 17:8, 9; Mal 2:7
Diu. 33:10Ẹk 30:7; Nọ 16:40
Diu. 33:10Le 1:9
Diu. 33:12Jẹ 49:27
Diu. 33:13Jẹ 49:22
Diu. 33:13Joṣ 16:1
Diu. 33:13Jẹ 49:25
Diu. 33:14Le 26:5; Sm 65:9
Diu. 33:15Joṣ 17:17, 18
Diu. 33:16Di 8:7, 8
Diu. 33:16Ẹk 3:4; Iṣe 7:30
Diu. 33:16Jẹ 37:7; 49:26; 1Kr 5:1, 2
Diu. 33:17Jẹ 48:19, 20
Diu. 33:18Jẹ 49:13
Diu. 33:18Jẹ 49:14
Diu. 33:20Jẹ 49:19
Diu. 33:20Joṣ 13:24-28
Diu. 33:21Nọ 32:1-5
Diu. 33:21Joṣ 22:1, 4
Diu. 33:22Jẹ 49:16
Diu. 33:22Ond 13:2, 24; 15:8, 20; 16:30
Diu. 33:22Joṣ 19:47
Diu. 33:23Jẹ 49:21
Diu. 33:24Jẹ 49:20
Diu. 33:25Di 8:7, 9
Diu. 33:26Ẹk 15:11
Diu. 33:26Ais 44:2
Diu. 33:26Sm 68:32-34
Diu. 33:27Sm 46:11; 91:2
Diu. 33:27Ais 40:11
Diu. 33:27Di 9:3
Diu. 33:27Di 31:3, 4
Diu. 33:28Di 8:7, 8
Diu. 33:28Di 11:11
Diu. 33:29Sm 33:12; 144:15; 146:5
Diu. 33:29Di 4:7; 2Sa 7:23; Sm 147:20
Diu. 33:29Sm 27:1; Ais 12:2
Diu. 33:29Sm 115:9
Diu. 33:29Sm 66:3
  • Bíbélì Mímọ́ ti Ìtumọ̀ Ayé Tuntun
  • 1
  • 2
  • 3
  • 4
  • 5
  • 6
  • 7
  • 8
  • 9
  • 10
  • 11
  • 12
  • 13
  • 14
  • 15
  • 16
  • 17
  • 18
  • 19
  • 20
  • 21
  • 22
  • 23
  • 24
  • 25
  • 26
  • 27
  • 28
  • 29
Bíbélì Mímọ́ ti Ìtumọ̀ Ayé Tuntun
Diutarónómì 33:1-29

Diutarónómì

33 Bí Mósè èèyàn Ọlọ́run tòótọ́ ṣe súre fún àwọn ọmọ Ísírẹ́lì kó tó kú nìyí.+ 2 Ó sọ pé:

“Jèhófà wá láti Sínáì,+

Ó sì tàn sórí wọn láti Séírì.

Ògo rẹ̀ tàn láti agbègbè olókè Páránì,+

Ọ̀kẹ́ àìmọye* àwọn ẹni mímọ́+ sì wà pẹ̀lú rẹ̀,

Àwọn jagunjagun+ rẹ̀ wà ní ọwọ́ ọ̀tún rẹ̀.

 3 Ó nífẹ̀ẹ́ àwọn èèyàn rẹ̀;+

Gbogbo ẹni mímọ́ wọn wà ní ọwọ́ rẹ.+

Wọ́n jókòó sẹ́gbẹ̀ẹ́ ẹsẹ̀ rẹ;+

Wọ́n bẹ̀rẹ̀ sí í tẹ́tí sí ọ̀rọ̀ rẹ.+

 4 (Mósè fún wa ní àṣẹ kan, òfin kan,+

Tó jẹ́ ohun ìní ìjọ Jékọ́bù.)+

 5 Ó sì di ọba ní Jéṣúrúnì,*+

Nígbà tí àwọn olórí àwọn èèyàn náà kóra jọ,+

Pẹ̀lú gbogbo ẹ̀yà Ísírẹ́lì.+

 6 Kí Rúbẹ́nì yè, kó má sì kú,+

Kí iye àwọn èèyàn rẹ̀ má sì dín kù.”+

 7 Ó sì súre fún Júdà+ pé:

“Ìwọ Jèhófà, gbọ́ ohùn Júdà,+

Kí o sì mú un pa dà sọ́dọ̀ àwọn èèyàn rẹ̀.

Ọwọ́ rẹ̀ ti gbèjà* ohun tó jẹ́ tirẹ̀,

Ràn án lọ́wọ́ kó lè borí àwọn ọ̀tá rẹ̀.”+

 8 Ó sọ nípa Léfì pé:+

“Túmímù rẹ* àti Úrímù  + rẹ jẹ́ ti ẹni tó jẹ́ adúróṣinṣin sí ọ,+

Ẹni tí o dán wò ní Másà.+

O bẹ̀rẹ̀ sí í bá a fà á lẹ́gbẹ̀ẹ́ omi Mẹ́ríbà,+

  9 Ẹni tó sọ nípa bàbá àti ìyá rẹ̀ pé, ‘Mi ò kà wọ́n sí.’

Ó tiẹ̀ tún kọ àwọn arákùnrin rẹ̀,+

Ó sì pa àwọn ọmọ rẹ̀ tì.

Torí wọ́n tẹ̀ lé ọ̀rọ̀ rẹ,

Wọ́n sì pa májẹ̀mú rẹ mọ́.+

 10 Jẹ́ kí wọ́n fi àwọn ìdájọ́ rẹ kọ́ Jékọ́bù,+

Kí wọ́n sì fi Òfin rẹ kọ́ Ísírẹ́lì.+

Jẹ́ kí wọ́n sun tùràrí láti mú òórùn dídùn jáde sí ọ*+

Àti odindi ẹbọ lórí pẹpẹ rẹ.+

 11 Bù kún agbára rẹ̀, Jèhófà,

Kí inú rẹ sì dùn sí iṣẹ́ ọwọ́ rẹ̀.

Fọ́ ẹsẹ̀* àwọn tó dìde sí i,

Kí àwọn tó kórìíra rẹ̀ má bàa dìde mọ́.”

 12 Ó sọ nípa Bẹ́ńjámínì pé:+

“Kí ẹni ọ̀wọ́n Jèhófà máa gbé láìséwu lọ́dọ̀ rẹ̀;

Bó ṣe ń dáàbò bò ó ní gbogbo ọjọ́,

Á máa gbé láàárín èjìká rẹ̀.”

 13 Ó sọ nípa Jósẹ́fù pé:+

“Kí Jèhófà bù kún ilẹ̀ rẹ̀+

Pẹ̀lú àwọn ohun tó dáa láti ọ̀run,

Pẹ̀lú ìrì àti omi tó ń sun láti ilẹ̀,+

 14 Pẹ̀lú àwọn ohun tó dáa tí oòrùn mú jáde,

Àti ohun tó dáa tó ń mú jáde lóṣooṣù,+

 15 Pẹ̀lú àwọn ohun tó dáa jù láti àwọn òkè àtijọ́,*+

Àti àwọn ohun tó dáa láti àwọn òkè tó ti wà tipẹ́,

 16 Pẹ̀lú àwọn ohun tó dáa ní ayé àti ohun tó kún inú rẹ̀,+

Kí Ẹni tó ń gbé inú igi ẹlẹ́gùn-ún+ sì tẹ́wọ́ gbà á.

Kí wọ́n wá sí orí Jósẹ́fù,

Sí àtàrí ẹni tí a yà sọ́tọ̀ lára àwọn arákùnrin rẹ̀.+

 17 Iyì rẹ̀ dà bíi ti àkọ́bí akọ màlúù,

Ìwo akọ màlúù igbó sì ni àwọn ìwo rẹ̀.

Ó máa fi ti* àwọn èèyàn,

Gbogbo wọn pa pọ̀ títí dé àwọn ìkángun ayé.

Ẹgbẹẹgbàárùn-ún Éfúrémù  + ni wọ́n,

Ẹgbẹẹgbẹ̀rún Mánásè sì ni wọ́n.”

 18 Ó sọ nípa Sébúlúnì pé:+

“Ìwọ Sébúlúnì, máa yọ̀ bí o ṣe ń jáde lọ,

Àti ìwọ Ísákà, nínú àwọn àgọ́ rẹ.+

 19 Wọ́n á pe àwọn èèyàn wá sórí òkè.

Ibẹ̀ ni wọ́n á ti rú àwọn ẹbọ òdodo.

Torí wọ́n á kó látinú ọ̀pọ̀ rẹpẹtẹ ọrọ̀ inú* òkun,

Àti àwọn ohun* tó fara pa mọ́ sínú iyẹ̀pẹ̀.”

 20 Ó sọ nípa Gádì pé:+

“Ìbùkún ni fún ẹni tó ń mú kí àwọn ààlà Gádì+ fẹ̀ sí i.

Ó dùbúlẹ̀ síbẹ̀ bíi kìnnìún,

Tó múra tán láti fa apá ya, àní àtàrí.

 21 Ó máa mú ìpín àkọ́kọ́ fún ara rẹ̀,+

Torí ibẹ̀ ni ìpín látọwọ́ ẹni tó fúnni ní òfin wà ní ìpamọ́.+

Àwọn olórí àwọn èèyàn náà máa kóra jọ.

Ó máa mú òdodo Jèhófà ṣẹ

Àti àwọn ìdájọ́ rẹ̀ pẹ̀lú Ísírẹ́lì.”

 22 Ó sọ nípa Dánì pé:+

“Ọmọ kìnnìún ni Dánì.+

Ó máa bẹ́ jáde láti Báṣánì.”+

 23 Ó sọ nípa Náfútálì pé:+

“Jèhófà ti tẹ́wọ́ gba Náfútálì

Ó sì ti bù kún un lọ́pọ̀lọpọ̀.

Gba ìwọ̀ oòrùn àti gúúsù.”

 24 Ó sọ nípa Áṣérì pé:+

“A fi àwọn ọmọ bù kún Áṣérì.

Kó rí ojúure àwọn arákùnrin rẹ̀,

Kó sì ki ẹsẹ̀ rẹ̀ bọ inú òróró.*

 25 Irin àti bàbà ni wọ́n fi ṣe ohun tí wọ́n fi ń ti ẹnubodè rẹ,+

O sì máa wà láìséwu ní gbogbo ọjọ́ rẹ.*

 26 Kò sí ẹni tó dà bí Ọlọ́run tòótọ́+ Jéṣúrúnì,+

Tó ń la ọ̀run kọjá kó lè ràn ọ́ lọ́wọ́,

Tó sì ń gun àwọsánmà* nínú ọlá ńlá rẹ̀.+

 27 Ọlọ́run jẹ́ ibi ààbò láti ìgbà àtijọ́,+

Ọwọ́ ayérayé rẹ̀ wà lábẹ́ rẹ.+

Ó máa lé ọ̀tá kúrò níwájú rẹ,+

Ó sì máa sọ pé, ‘Pa wọ́n run!’+

 28 Ísírẹ́lì á máa gbé láìséwu,

Orísun Jékọ́bù sì máa wà lọ́tọ̀,

Ní ilẹ̀ tí ọkà àti wáìnì tuntun+ wà,

Tí ìrì á máa sẹ̀ lójú ọ̀run rẹ̀.+

 29 Aláyọ̀ ni ọ́, ìwọ Ísírẹ́lì!+

Ta ló dà bí rẹ,+

Àwọn èèyàn tó ń gbádùn ìgbàlà Jèhófà,+

Apata tó ń dáàbò bò ọ́,+

Àti idà ọlá ńlá rẹ?

Àwọn ọ̀tá rẹ máa ba búrúbúrú níwájú rẹ,+

Wàá sì rìn lórí ẹ̀yìn* wọn.”

Yorùbá Publications (1987-2025)
Jáde
Wọlé
  • Yorùbá
  • Fi Ráńṣẹ́
  • Èyí tí mo fẹ́ràn jù
  • Copyright © 2025 Watch Tower Bible and Tract Society of Pennsylvania
  • Àdéhùn Nípa Lílò
  • Òfin
  • Ètò Nípa Ìsọfúnni Rẹ
  • JW.ORG
  • Wọlé
Fi Ráńṣẹ́