ÀKÁ ÌWÉ ORÍ ÍNTÁNẸ́Ẹ̀TÌ ti Watchtower
ÀKÁ ÌWÉ ORÍ ÍŃTÁNẸ́Ẹ̀TÌ
ti Watchtower
Yorùbá
ọ́
  • ẹ
  • ọ
  • ṣ
  • ń
  • ẹ́
  • ẹ̀
  • ọ́
  • ọ̀
  • BÍBÉLÌ
  • ÌTẸ̀JÁDE
  • ÌPÀDÉ
  • Sáàmù 102
  • Bíbélì Mímọ́ ti Ìtumọ̀ Ayé Tuntun

Kò sí fídíò kankan ní apá yìí.

Má bínú, fídíò yìí kò jáde.

Ohun Tó Wà Nínú Ìwé Sáàmù

      • Àdúrà ẹni tí a ni lára nígbà tí nǹkan tojú sú u

        • “Mo dà bí ẹyẹ tó dá wà lórí òrùlé” (7)

        • ‘Àwọn ọjọ́ mi jẹ́ òjìji tó ń pa rẹ́ lọ’ (11)

        • “Jèhófà máa tún Síónì kọ́” (16)

        • Jèhófà wà títí láé (26, 27)

Sáàmù 102:àkọlé

Àlàyé ìsàlẹ́ ìwé

  • *

    Tàbí “tí àárẹ̀ mú un.”

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +Sm 61:2; 142:2

Atọ́ka

  • Ìwé Ìwádìí

Sáàmù 102:1

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +Sm 55:1; Da 9:17
  • +Ẹk 2:23

Sáàmù 102:2

Àlàyé ìsàlẹ́ ìwé

  • *

    Tàbí “Bẹ̀rẹ̀ kí o sì fetí sí mi.”

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +Sm 27:9; Ida 1:20
  • +Sm 143:7; Ais 65:24

Sáàmù 102:3

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +Ida 1:13

Sáàmù 102:4

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +Sm 143:4

Sáàmù 102:5

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +Sm 6:6; 38:8
  • +Job 19:20; Owe 17:22

Sáàmù 102:7

Àlàyé ìsàlẹ́ ìwé

  • *

    Tàbí kó jẹ́, “Mo ti rù kan eegun.”

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +Sm 38:11

Atọ́ka

  • Ìwé Ìwádìí

    Ilé Ìṣọ́,

    3/15/2014, ojú ìwé 16

Sáàmù 102:8

Àlàyé ìsàlẹ́ ìwé

  • *

    Tàbí “tó ń dá yẹ̀yẹ́ mi sílẹ̀.”

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +Sm 31:11; 74:10; 79:4

Sáàmù 102:9

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +Ida 3:15
  • +Sm 80:5

Sáàmù 102:11

Àlàyé ìsàlẹ́ ìwé

  • *

    Tàbí “òjìji àṣálẹ́.”

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +Sm 39:5
  • +Job 14:1, 2; Sm 102:4

Sáàmù 102:12

Àlàyé ìsàlẹ́ ìwé

  • *

    Tàbí “Orúkọ rẹ yóò sì wà.” Ní Héb., “Ìrántí.”

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +Sm 90:2
  • +Ẹk 3:15

Atọ́ka

  • Ìwé Ìwádìí

    Ilé Ìṣọ́,

    3/15/2014, ojú ìwé 16

Sáàmù 102:13

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +Ais 49:15
  • +Ais 60:10
  • +Ẹsr 1:1, 2; Ais 40:2; Da 9:2

Sáàmù 102:14

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +Ne 2:3; Sm 137:5
  • +Sm 79:1

Sáàmù 102:15

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +Ais 60:3; Sek 8:22

Sáàmù 102:16

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +Sm 147:2; Jer 33:7
  • +Ais 60:1

Sáàmù 102:17

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +Da 9:20, 21
  • +Sm 22:24

Sáàmù 102:18

Àlàyé ìsàlẹ́ ìwé

  • *

    Ní Héb., “dá.”

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +Sm 78:4; Ro 15:4

Sáàmù 102:19

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +2Kr 16:9

Sáàmù 102:20

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +Ẹk 3:7; Ais 61:1
  • +2Kr 33:12, 13; Sm 79:11

Sáàmù 102:21

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +Sm 9:13, 14; 22:22; Ais 51:11

Sáàmù 102:22

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +Ais 11:10; 49:22; 60:3

Sáàmù 102:24

Àlàyé ìsàlẹ́ ìwé

  • *

    Ní Héb., “Má ṣe mú mi kúrò ní ààbọ̀ àwọn ọjọ́ mi.”

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +Sm 90:2; Hab 1:12; Ifi 1:8

Sáàmù 102:25

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +Sm 8:3; Ais 48:13; Heb 1:10-12

Atọ́ka

  • Ìwé Ìwádìí

    Ilé Ìṣọ́,

    7/1/2011, ojú ìwé 27

    1/1/2006, ojú ìwé 30

Sáàmù 102:26

Atọ́ka

  • Ìwé Ìwádìí

    Ilé Ìṣọ́ (Ẹ̀dà Tá À Ń Fi Sóde),

    No. 1 2018 ojú ìwé 6

    Ilé Ìṣọ́,

    7/1/2011, ojú ìwé 27-28

    4/1/2008, ojú ìwé 11-12

    1/1/2006, ojú ìwé 30

Sáàmù 102:27

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +Job 36:26; Mal 3:6; Jem 1:17

Atọ́ka

  • Ìwé Ìwádìí

    Ilé Ìṣọ́,

    3/15/2014, ojú ìwé 16

    7/1/2011, ojú ìwé 27

Sáàmù 102:28

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +Ais 66:22

Àwọn míì

Sm 102:àkọléSm 61:2; 142:2
Sm 102:1Sm 55:1; Da 9:17
Sm 102:1Ẹk 2:23
Sm 102:2Sm 27:9; Ida 1:20
Sm 102:2Sm 143:7; Ais 65:24
Sm 102:3Ida 1:13
Sm 102:4Sm 143:4
Sm 102:5Sm 6:6; 38:8
Sm 102:5Job 19:20; Owe 17:22
Sm 102:7Sm 38:11
Sm 102:8Sm 31:11; 74:10; 79:4
Sm 102:9Ida 3:15
Sm 102:9Sm 80:5
Sm 102:11Sm 39:5
Sm 102:11Job 14:1, 2; Sm 102:4
Sm 102:12Sm 90:2
Sm 102:12Ẹk 3:15
Sm 102:13Ais 49:15
Sm 102:13Ais 60:10
Sm 102:13Ẹsr 1:1, 2; Ais 40:2; Da 9:2
Sm 102:14Ne 2:3; Sm 137:5
Sm 102:14Sm 79:1
Sm 102:15Ais 60:3; Sek 8:22
Sm 102:16Sm 147:2; Jer 33:7
Sm 102:16Ais 60:1
Sm 102:17Da 9:20, 21
Sm 102:17Sm 22:24
Sm 102:18Sm 78:4; Ro 15:4
Sm 102:192Kr 16:9
Sm 102:20Ẹk 3:7; Ais 61:1
Sm 102:202Kr 33:12, 13; Sm 79:11
Sm 102:21Sm 9:13, 14; 22:22; Ais 51:11
Sm 102:22Ais 11:10; 49:22; 60:3
Sm 102:24Sm 90:2; Hab 1:12; Ifi 1:8
Sm 102:25Sm 8:3; Ais 48:13; Heb 1:10-12
Sm 102:27Job 36:26; Mal 3:6; Jem 1:17
Sm 102:28Ais 66:22
  • Bíbélì Mímọ́ ti Ìtumọ̀ Ayé Tuntun
  • 1
  • 2
  • 3
  • 4
  • 5
  • 6
  • 7
  • 8
  • 9
  • 10
  • 11
  • 12
  • 13
  • 14
  • 15
  • 16
  • 17
  • 18
  • 19
  • 20
  • 21
  • 22
  • 23
  • 24
  • 25
  • 26
  • 27
  • 28
Bíbélì Mímọ́ ti Ìtumọ̀ Ayé Tuntun
Sáàmù 102:1-28

Sáàmù

Àdúrà ẹni tí ìnilára bá nígbà tí nǹkan tojú sú u,* tó sì ń sọ ẹ̀dùn ọkàn rẹ̀ níwájú Jèhófà.+

102 Jèhófà, gbọ́ àdúrà mi;+

Jẹ́ kí igbe mi fún ìrànlọ́wọ́ dé ọ̀dọ̀ rẹ.+

 2 Má fi ojú rẹ pa mọ́ fún mi nígbà tí mo wà nínú wàhálà.+

Tẹ́tí sí mi;*

Tètè dá mi lóhùn nígbà tí mo bá pè ọ́.+

 3 Nítorí àwọn ọjọ́ mi ń pa rẹ́ lọ bí èéfín,

Àwọn egungun mi sì ti di dúdú bí ibi ìdáná.+

 4 Ọkàn mi dà bíi koríko tí a gé, tó sì ti rọ,+

Nítorí mi ò rántí jẹ oúnjẹ mi.

 5 Nítorí bí mo ṣe ń kérora gidigidi,+

Egungun mi ti lẹ̀ mọ́ ẹran ara mi.+

 6 Mo dà bí ẹyẹ òfú tó wà ní aginjù;

Mo dà bí òwìwí kékeré tó wà láàárín àwókù.

 7 Mi ò rí oorun sùn;*

Mo dà bí ẹyẹ tó dá wà lórí òrùlé.+

 8 Àwọn ọ̀tá mi ń pẹ̀gàn mi láti àárọ̀ ṣúlẹ̀.+

Àwọn tó ń fi mí ṣẹ̀sín* ń lo orúkọ mi tí wọ́n bá fẹ́ gégùn-ún.

 9 Eérú ni mo fi ń ṣe oúnjẹ jẹ,+

Omijé sì ti dà pọ̀ mọ́ ohun tí mò ń mu,+

10 Nítorí ìbínú rẹ àti ìrunú rẹ,

O gbé mi sókè kí o lè jù mí sí ẹ̀gbẹ́ kan.

11 Àwọn ọjọ́ mi dà bí òjìji tó ń pa rẹ́ lọ,*+

Mo sì ń rọ bíi koríko.+

12 Àmọ́, Jèhófà, o wà títí láé,+

Òkìkí rẹ yóò sì máa kàn* láti ìran dé ìran.+

13 Ó dájú pé wàá dìde, wàá sì ṣàánú Síónì,+

Torí àkókò ti tó láti ṣe ojú rere sí i;+

Àkókò tí a dá ti pé.+

14 Nítorí àwọn ìránṣẹ́ rẹ fẹ́ràn àwọn òkúta rẹ̀,+

Kódà, wọ́n nífẹ̀ẹ́ erùpẹ̀ rẹ̀.+

15 Àwọn orílẹ̀-èdè yóò máa bẹ̀rù orúkọ Jèhófà,

Gbogbo ọba ayé yóò sì máa bẹ̀rù ògo rẹ.+

16 Jèhófà máa tún Síónì kọ́;+

Á fara hàn nínú ògo rẹ̀.+

17 Á fetí sí àdúrà àwọn òtòṣì,+

Kò sì ní kó àdúrà wọn dà nù.+

18 A kọ èyí sílẹ̀ torí ìran tó ń bọ̀,+

Kí àwọn èèyàn tí a ó bí* lè yin Jáà.

19 Ó ń bojú wolẹ̀ láti ibi gíga rẹ̀ mímọ́,+

Láti ọ̀run, Jèhófà ń wo ayé,

20 Kí ó lè gbọ́ bí ẹlẹ́wọ̀n ṣe ń kérora,+

Kí ó lè dá àwọn tí wọ́n ti dájọ́ ikú fún sílẹ̀,+

21 Ká lè kéde orúkọ Jèhófà ní Síónì+

Àti ìyìn rẹ̀ ní Jerúsálẹ́mù,

22 Nígbà tí àwọn èèyàn àti àwọn ìjọba

Bá kóra jọ láti sin Jèhófà.+

23 Ó gba agbára mi láìtọ́jọ́;

Ó gé ọjọ́ ayé mi kúrú.

24 Mo sọ pé: “Ìwọ Ọlọ́run mi,

Má ṣe dá ẹ̀mí mi légbodò,*

Ìwọ tí àwọn ọdún rẹ lọ láti ìran dé ìran.+

25 Tipẹ́tipẹ́ lo ti fi ìpìlẹ̀ ayé sọlẹ̀,

Ọ̀run sì jẹ́ iṣẹ́ ọwọ́ rẹ.+

26 Wọ́n á ṣègbé, àmọ́ ìwọ á máa wà nìṣó;

Gbogbo wọn á gbó bí aṣọ.

Wàá pààrọ̀ wọn bí aṣọ, wọn ò sì ní sí mọ́.

27 Àmọ́ ìwọ kò yí pa dà, àwọn ọdún rẹ kò sì ní dópin láé.+

28 Ọmọ àwọn ìránṣẹ́ rẹ yóò máa wà láìséwu,

A ó sì fìdí àtọmọdọ́mọ wọn múlẹ̀ gbọn-in níwájú rẹ.”+

Yorùbá Publications (1987-2025)
Jáde
Wọlé
  • Yorùbá
  • Fi Ráńṣẹ́
  • Èyí tí mo fẹ́ràn jù
  • Copyright © 2025 Watch Tower Bible and Tract Society of Pennsylvania
  • Àdéhùn Nípa Lílò
  • Òfin
  • Ètò Nípa Ìsọfúnni Rẹ
  • JW.ORG
  • Wọlé
Fi Ráńṣẹ́