ÀKÁ ÌWÉ ORÍ ÍNTÁNẸ́Ẹ̀TÌ ti Watchtower
ÀKÁ ÌWÉ ORÍ ÍŃTÁNẸ́Ẹ̀TÌ
ti Watchtower
Yorùbá
ọ́
  • ẹ
  • ọ
  • ṣ
  • ń
  • ẹ́
  • ẹ̀
  • ọ́
  • ọ̀
  • BÍBÉLÌ
  • ÌTẸ̀JÁDE
  • ÌPÀDÉ
  • Jeremáyà 50
  • Bíbélì Mímọ́ ti Ìtumọ̀ Ayé Tuntun

Kò sí fídíò kankan ní apá yìí.

Má bínú, fídíò yìí kò jáde.

Ohun Tó Wà Nínú Ìwé Jeremáyà

      • Àsọtẹ́lẹ̀ lórí Bábílónì (1-46)

        • Ẹ sá kúrò nínú Bábílónì (8)

        • A ó mú Ísírẹ́lì pa dà wá (17-19)

        • A ó mú kí odò Bábílónì gbẹ (38)

        • Ẹnikẹ́ni kò ní gbé Bábílónì mọ́ (39, 40)

Jeremáyà 50:1

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +Ais 13:1

Atọ́ka

  • Ìwé Ìwádìí

    “Ete aiyeraiye,” ojú ìwé 18

Jeremáyà 50:2

Àlàyé ìsàlẹ́ ìwé

  • *

    Tàbí “fi òpó ṣe àmì.”

  • *

    Ó ṣeé ṣe kí ọ̀rọ̀ Hébérù yìí ní í ṣe pẹ̀lú ọ̀rọ̀ tí wọ́n ń lò fún “ìgbẹ́,” wọ́n sì máa ń lò ó fún ohun tí wọ́n bá kórìíra.

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +Jer 51:8; Ifi 14:8
  • +Ais 46:1; Jer 51:44

Jeremáyà 50:3

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +Ais 13:17; Jer 51:11, 48

Jeremáyà 50:4

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +Ais 11:12; Jer 3:18; Ho 1:11
  • +Jer 31:8, 9
  • +Ho 3:5

Jeremáyà 50:5

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +Ais 35:10
  • +Jer 31:31

Jeremáyà 50:6

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +Ais 53:6
  • +Jer 10:21; 23:2; Isk 34:2, 6

Jeremáyà 50:7

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +Sm 79:6, 7

Atọ́ka

  • Ìwé Ìwádìí

    Àwọn Ìtẹ̀jáde Tá A Tọ́ka sí Nínú Ìwé Ìpàdé, 5/2017,

Jeremáyà 50:8

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +Ais 48:20; Jer 51:6, 45; Sek 2:7; 2Kọ 6:17; Ifi 18:2, 4

Jeremáyà 50:9

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +Ais 21:2; Jer 51:11, 27, 28, 48; Da 5:28, 30
  • +Ais 13:17, 18

Jeremáyà 50:10

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +Jer 25:12; 27:6, 7
  • +Ifi 17:16

Jeremáyà 50:11

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +Ida 1:21
  • +Ais 14:4-6; 47:6; Jer 30:16

Jeremáyà 50:12

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +Ais 47:8
  • +Ais 13:20, 21

Jeremáyà 50:13

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +Sek 1:15
  • +Jer 25:12
  • +Jer 51:37

Jeremáyà 50:14

Àlàyé ìsàlẹ́ ìwé

  • *

    Ní Héb., “fi okùn sí.”

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +Ais 13:18; Jer 51:11
  • +Jer 51:35, 36

Jeremáyà 50:15

Àlàyé ìsàlẹ́ ìwé

  • *

    Ní Héb., “fi ọwọ́ rẹ̀ fúnni.”

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +Jer 51:58
  • +Jer 51:6, 11
  • +Sm 137:8; Ifi 18:6

Jeremáyà 50:16

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +Jer 51:23
  • +Ais 13:14; Jer 51:9

Jeremáyà 50:17

Àlàyé ìsàlẹ́ ìwé

  • *

    Ní Héb., “Nebukadirésárì,” ọ̀nà míì tí wọ́n ń gbà kọ orúkọ yìí.

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +Jer 23:1; 50:6; Isk 34:5
  • +Jer 2:15
  • +2Ọb 17:6; Ais 8:7
  • +2Ọb 25:1; 2Kr 36:17; Jer 4:7

Jeremáyà 50:18

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +2Ọb 19:35; Ais 14:25; Sef 2:13

Jeremáyà 50:19

Àlàyé ìsàlẹ́ ìwé

  • *

    Tàbí “ọkàn rẹ̀ á.”

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +Ais 11:16; 65:10; Jer 23:3; 33:7; Isk 34:14; Mik 2:12
  • +Mik 7:14
  • +Jer 31:6
  • +Ọbd 19

Jeremáyà 50:20

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +Ais 44:22; Jer 31:34; Mik 7:19

Jeremáyà 50:21

Àlàyé ìsàlẹ́ ìwé

  • *

    Tàbí “sì pa wọ́n run pátápátá.”

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +Isk 23:22, 23

Jeremáyà 50:23

Àlàyé ìsàlẹ́ ìwé

  • *

    Ìyẹn, hámà ńlá tí àwọn alágbẹ̀dẹ máa ń lò.

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +Ais 14:5, 6; Jer 51:20
  • +Jer 51:41; Ifi 18:15, 16

Jeremáyà 50:24

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +Jer 51:31; Da 5:30; Ifi 18:8

Jeremáyà 50:25

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +Ais 13:5; Jer 51:11

Jeremáyà 50:26

Àlàyé ìsàlẹ́ ìwé

  • *

    Tàbí “pa á run pátápátá.”

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +Jer 51:27
  • +Jer 50:10
  • +Ais 14:22, 23

Jeremáyà 50:27

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +Ais 34:6, 7; Isk 39:18

Jeremáyà 50:28

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +Sm 94:1; Jer 51:11

Jeremáyà 50:29

Àlàyé ìsàlẹ́ ìwé

  • *

    Ní Héb., “fi okùn sí.”

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +Jer 50:14
  • +Sm 137:8; Jer 51:56
  • +Ida 3:64; Ifi 18:6
  • +Ais 14:13

Jeremáyà 50:30

Àlàyé ìsàlẹ́ ìwé

  • *

    Ní Héb., “ni a ó pa lẹ́nu mọ́.”

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +Ais 13:17, 18

Jeremáyà 50:31

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +Jer 51:25
  • +Ais 14:13; Da 4:30

Jeremáyà 50:32

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +Jer 51:26

Jeremáyà 50:33

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +Ais 47:6
  • +Ais 14:17

Jeremáyà 50:34

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +Ais 41:14; Ifi 18:8
  • +Ais 47:4
  • +Ida 3:59
  • +Ais 14:3, 4
  • +Jer 51:24

Jeremáyà 50:35

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +Ais 47:13; Jer 51:57; Da 5:7

Jeremáyà 50:36

Àlàyé ìsàlẹ́ ìwé

  • *

    Tàbí “àwọn wòlíì èké.”

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +Jer 51:30

Jeremáyà 50:37

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +Ais 13:8
  • +Ais 45:3

Jeremáyà 50:38

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +Ais 44:27; Jer 51:36, 37; Ifi 16:12
  • +Ais 46:1; Jer 51:44, 52; Da 5:1, 4

Atọ́ka

  • Ìwé Ìwádìí

    Jeremáyà, ojú ìwé 161-162

    Àsọtẹ́lẹ̀ Dáníẹ́lì, ojú ìwé 150-151

    Ìmọ̀, ojú ìwé 18

Jeremáyà 50:39

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +Ais 13:20, 21; Jer 51:37; Ifi 18:2
  • +Jer 25:12; 51:43, 64

Jeremáyà 50:40

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +Ais 13:19
  • +Jẹ 19:24, 25; Jud 7
  • +Jer 51:26

Jeremáyà 50:41

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +Ais 45:1; Jer 51:11, 27, 28
  • +Ais 13:5, 17

Jeremáyà 50:42

Àlàyé ìsàlẹ́ ìwé

  • *

    Tàbí “ẹ̀ṣín.”

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +Jer 50:9
  • +Sm 137:8; Ais 13:17, 18
  • +Jer 51:42
  • +Jer 51:27

Atọ́ka

  • Ìwé Ìwádìí

    Ilé Ìṣọ́,

    11/15/2001, ojú ìwé 26

Jeremáyà 50:43

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +Jer 51:31
  • +Da 5:6

Jeremáyà 50:44

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +Ais 41:25
  • +Jer 49:19-21

Jeremáyà 50:45

Àlàyé ìsàlẹ́ ìwé

  • *

    Tàbí “ìmọ̀ràn.”

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +Jer 51:11
  • +Ais 13:1, 20; Jer 51:43

Atọ́ka

  • Ìwé Ìwádìí

    “Ete aiyeraiye,” ojú ìwé 18

Jeremáyà 50:46

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +Ifi 18:9

Àwọn míì

Jer. 50:1Ais 13:1
Jer. 50:2Jer 51:8; Ifi 14:8
Jer. 50:2Ais 46:1; Jer 51:44
Jer. 50:3Ais 13:17; Jer 51:11, 48
Jer. 50:4Ais 11:12; Jer 3:18; Ho 1:11
Jer. 50:4Jer 31:8, 9
Jer. 50:4Ho 3:5
Jer. 50:5Ais 35:10
Jer. 50:5Jer 31:31
Jer. 50:6Ais 53:6
Jer. 50:6Jer 10:21; 23:2; Isk 34:2, 6
Jer. 50:7Sm 79:6, 7
Jer. 50:8Ais 48:20; Jer 51:6, 45; Sek 2:7; 2Kọ 6:17; Ifi 18:2, 4
Jer. 50:9Ais 21:2; Jer 51:11, 27, 28, 48; Da 5:28, 30
Jer. 50:9Ais 13:17, 18
Jer. 50:10Jer 25:12; 27:6, 7
Jer. 50:10Ifi 17:16
Jer. 50:11Ida 1:21
Jer. 50:11Ais 14:4-6; 47:6; Jer 30:16
Jer. 50:12Ais 47:8
Jer. 50:12Ais 13:20, 21
Jer. 50:13Sek 1:15
Jer. 50:13Jer 25:12
Jer. 50:13Jer 51:37
Jer. 50:14Ais 13:18; Jer 51:11
Jer. 50:14Jer 51:35, 36
Jer. 50:15Jer 51:58
Jer. 50:15Jer 51:6, 11
Jer. 50:15Sm 137:8; Ifi 18:6
Jer. 50:16Jer 51:23
Jer. 50:16Ais 13:14; Jer 51:9
Jer. 50:17Jer 23:1; 50:6; Isk 34:5
Jer. 50:17Jer 2:15
Jer. 50:172Ọb 17:6; Ais 8:7
Jer. 50:172Ọb 25:1; 2Kr 36:17; Jer 4:7
Jer. 50:182Ọb 19:35; Ais 14:25; Sef 2:13
Jer. 50:19Ais 11:16; 65:10; Jer 23:3; 33:7; Isk 34:14; Mik 2:12
Jer. 50:19Mik 7:14
Jer. 50:19Jer 31:6
Jer. 50:19Ọbd 19
Jer. 50:20Ais 44:22; Jer 31:34; Mik 7:19
Jer. 50:21Isk 23:22, 23
Jer. 50:23Ais 14:5, 6; Jer 51:20
Jer. 50:23Jer 51:41; Ifi 18:15, 16
Jer. 50:24Jer 51:31; Da 5:30; Ifi 18:8
Jer. 50:25Ais 13:5; Jer 51:11
Jer. 50:26Jer 51:27
Jer. 50:26Jer 50:10
Jer. 50:26Ais 14:22, 23
Jer. 50:27Ais 34:6, 7; Isk 39:18
Jer. 50:28Sm 94:1; Jer 51:11
Jer. 50:29Jer 50:14
Jer. 50:29Sm 137:8; Jer 51:56
Jer. 50:29Ida 3:64; Ifi 18:6
Jer. 50:29Ais 14:13
Jer. 50:30Ais 13:17, 18
Jer. 50:31Jer 51:25
Jer. 50:31Ais 14:13; Da 4:30
Jer. 50:32Jer 51:26
Jer. 50:33Ais 47:6
Jer. 50:33Ais 14:17
Jer. 50:34Ais 41:14; Ifi 18:8
Jer. 50:34Ais 47:4
Jer. 50:34Ida 3:59
Jer. 50:34Ais 14:3, 4
Jer. 50:34Jer 51:24
Jer. 50:35Ais 47:13; Jer 51:57; Da 5:7
Jer. 50:36Jer 51:30
Jer. 50:37Ais 13:8
Jer. 50:37Ais 45:3
Jer. 50:38Ais 44:27; Jer 51:36, 37; Ifi 16:12
Jer. 50:38Ais 46:1; Jer 51:44, 52; Da 5:1, 4
Jer. 50:39Ais 13:20, 21; Jer 51:37; Ifi 18:2
Jer. 50:39Jer 25:12; 51:43, 64
Jer. 50:40Ais 13:19
Jer. 50:40Jẹ 19:24, 25; Jud 7
Jer. 50:40Jer 51:26
Jer. 50:41Ais 45:1; Jer 51:11, 27, 28
Jer. 50:41Ais 13:5, 17
Jer. 50:42Jer 50:9
Jer. 50:42Sm 137:8; Ais 13:17, 18
Jer. 50:42Jer 51:42
Jer. 50:42Jer 51:27
Jer. 50:43Jer 51:31
Jer. 50:43Da 5:6
Jer. 50:44Ais 41:25
Jer. 50:44Jer 49:19-21
Jer. 50:45Jer 51:11
Jer. 50:45Ais 13:1, 20; Jer 51:43
Jer. 50:46Ifi 18:9
  • Bíbélì Mímọ́ ti Ìtumọ̀ Ayé Tuntun
  • 1
  • 2
  • 3
  • 4
  • 5
  • 6
  • 7
  • 8
  • 9
  • 10
  • 11
  • 12
  • 13
  • 14
  • 15
  • 16
  • 17
  • 18
  • 19
  • 20
  • 21
  • 22
  • 23
  • 24
  • 25
  • 26
  • 27
  • 28
  • 29
  • 30
  • 31
  • 32
  • 33
  • 34
  • 35
  • 36
  • 37
  • 38
  • 39
  • 40
  • 41
  • 42
  • 43
  • 44
  • 45
  • 46
Bíbélì Mímọ́ ti Ìtumọ̀ Ayé Tuntun
Jeremáyà 50:1-46

Jeremáyà

50 Ọ̀rọ̀ tí Jèhófà sọ nípa Bábílónì,+ nípa ilẹ̀ àwọn ará Kálídíà, nípasẹ̀ wòlíì Jeremáyà nìyí:

 2 “Ẹ sọ ọ́ láàárín àwọn orílẹ̀-èdè kí ẹ sì kéde rẹ̀.

Ẹ gbé àmì kan dúró,* ẹ sì kéde rẹ̀.

Ẹ má fi nǹkan kan pa mọ́!

Ẹ sọ pé, ‘Wọ́n ti gba Bábílónì.+

Ìtìjú ti bá Bélì.+

Méródákì wà nínú ìbẹ̀rù.

Ìtìjú ti bá àwọn ère rẹ̀.

Àwọn òrìṣà ẹ̀gbin rẹ̀* wà nínú ìbẹ̀rù.’

 3 Nítorí orílẹ̀-èdè kan ti wá gbéjà kò ó láti àríwá.+

Ó ti sọ ilẹ̀ rẹ̀ di ohun àríbẹ̀rù;

Kò sì sí ẹni tó ń gbé inú rẹ̀.

Èèyàn àti ẹranko ti fẹsẹ̀ fẹ;

Wọ́n ti lọ.”

4 “Ní àwọn ọjọ́ yẹn àti ní àkókò yẹn,” ni Jèhófà wí, “àwọn èèyàn Ísírẹ́lì àti àwọn èèyàn Júdà máa kóra jọ.+ Wọ́n á máa sunkún bí wọ́n ṣe ń rìn lọ,+ wọ́n á sì jọ máa wá Jèhófà Ọlọ́run wọn.+ 5 Wọ́n á béèrè ọ̀nà tó lọ sí Síónì, wọ́n á yíjú sí apá ibẹ̀,+ wọ́n á ní, ‘Ẹ wá, ẹ jẹ́ kí a bá Jèhófà dá májẹ̀mú tó máa wà títí láé, tí kò sì ní ṣeé gbàgbé.’+ 6 Àwọn èèyàn mi ti di agbo àgùntàn tó sọ nù.+ Àwọn olùṣọ́ àgùntàn wọn ti kó wọn ṣìnà.+ Wọ́n dà wọ́n lọ sórí àwọn òkè ńlá, wọ́n ń rìn látorí òkè ńlá dórí òkè kékeré. Wọ́n ti gbàgbé ibi ìsinmi wọn. 7 Gbogbo àwọn tó rí wọn ti pa wọ́n jẹ,+ àwọn ọ̀tá wọn sì ti sọ pé, ‘A ò jẹ̀bi, nítorí wọ́n ti ṣẹ Jèhófà, wọ́n ti ṣẹ ibùgbé òdodo àti ìrètí àwọn baba ńlá wọn, Jèhófà.’”

 8 “Ẹ sá kúrò nínú Bábílónì,

Ẹ jáde kúrò ní ilẹ̀ àwọn ará Kálídíà,+

Kí ẹ sì dà bí àgbò tó ń ṣíwájú agbo ẹran.

 9 Nítorí wò ó, màá gbé àwọn orílẹ̀-èdè ńlá dìde láti ilẹ̀ àríwá

Màá sì mú kí wọ́n gbéjà ko Bábílónì.+

Wọ́n á tò lọ́wọ̀ọ̀wọ́ láti gbógun tì í;

Ibẹ̀ ni wọ́n á ti gbà á.

Ọfà wọn dà bíi ti jagunjagun

Tó ń múni ṣòfò ọmọ;+

Wọn kì í pa dà wá lọ́wọ́ òfo.

10 Wọ́n á kó Kálídíà bí ẹrù ogun.+

Gbogbo àwọn tó bá ń kó ẹrù látinú rẹ̀ á tẹ́ ara wọn lọ́rùn,”+ ni Jèhófà wí.

11 “Nítorí ẹ̀ ń yọ̀,+ inú yín sì ń dùn

Nígbà tí ẹ̀ ń kó àwọn tó jẹ́ ogún mi lẹ́rù.+

Nítorí ẹ̀ ń fi ẹsẹ̀ talẹ̀ kiri bí abo ọmọ màlúù lórí koríko,

Ẹ sì ń yán bí akọ ẹṣin.

12 Ìtìjú ti bá ìyá yín.+

Ìjákulẹ̀ ti bá ẹni tó bí yín lọ́mọ.

Wò ó! Òun ló kéré jù láàárín àwọn orílẹ̀-èdè,

Aginjù tí kò lómi àti aṣálẹ̀.+

13 Nítorí ìbínú Jèhófà, ẹnikẹ́ni kò ní gbé inú rẹ̀;+

Á sì di ahoro látòkè délẹ̀.+

Ẹnikẹ́ni tó bá ń kọjá lọ lẹ́gbẹ̀ẹ́ Bábílónì á wò ó, ẹ̀rù á bà á

Á sì súfèé nítorí gbogbo ìyọnu rẹ̀.+

14 Ẹ jáde lọ́wọ̀ọ̀wọ́ láti gbógun ti Bábílónì láti ibi gbogbo,

Gbogbo ẹ̀yin tó ń tẹ* ọrun.

Ẹ ta á lọ́fà, ẹ má ṣe ṣẹ́ ọfà kankan kù,+

Nítorí Jèhófà ló ṣẹ̀ sí.+

15 Ẹ kígbe ogun mọ́ ọn láti ibi gbogbo.

Ó ti juwọ́ sílẹ̀.*

Àwọn òpó rẹ̀ ti ṣubú, àwọn ògiri rẹ̀ sì ti ya lulẹ̀,+

Nítorí ẹ̀san Jèhófà ni.+

Ẹ gbẹ̀san lára rẹ̀.

Bí ó ti ṣe síni ni kí ẹ ṣe sí i gẹ́lẹ́.+

16 Ẹ mú afúnrúgbìn kúrò ní Bábílónì

Àti ẹni tó ń lo dòjé ní ìgbà ìkórè.+

Nítorí idà tó ń hanni léèmọ̀, kálukú á pa dà sọ́dọ̀ àwọn èèyàn rẹ̀,

Kálukú á sì sá lọ sí ilẹ̀ rẹ̀.+

17 “Àwọn èèyàn Ísírẹ́lì jẹ́ àwọn àgùntàn tó tú ká.+ Àwọn kìnnìún ti fọ́n wọn ká.+ Ọba Ásíríà ló kọ́kọ́ jẹ wọ́n;+ lẹ́yìn náà, Nebukadinésárì* ọba Bábílónì jẹ egungun wọn.+ 18 Nítorí náà, ohun tí Jèhófà Ọlọ́run àwọn ọmọ ogun, Ọlọ́run Ísírẹ́lì sọ nìyí: ‘Wò ó, màá fìyà jẹ ọba Bábílónì àti ilẹ̀ rẹ̀ bí mo ṣe fìyà jẹ ọba Ásíríà.+ 19 Màá mú Ísírẹ́lì pa dà sí ibi ìjẹko rẹ̀,+ á jẹko ní Kámẹ́lì àti ní Báṣánì,+ á* sì ní ìtẹ́lọ́rùn lórí àwọn òkè Éfúrémù+ àti ti Gílíádì.’”+

20 “Ní ọjọ́ yẹn àti ní àkókò yẹn,” ni Jèhófà wí,

“A ó wá ẹ̀bi Ísírẹ́lì kiri,

Ṣùgbọ́n a kò ní rí ìkankan,

A kò sì ní rí àwọn ẹ̀ṣẹ̀ Júdà,

Nítorí màá dárí ji àwọn tí mo jẹ́ kí ó ṣẹ́ kù.”+

21 “Lọ gbéjà ko ilẹ̀ Mérátáímù àti àwọn tó ń gbé ní Pékódù.+

Jẹ́ kí wọ́n pa wọ́n ní ìpakúpa, sì jẹ́ kí wọ́n pa wọ́n rẹ́,”* ni Jèhófà wí.

“Ṣe gbogbo ohun tí mo ti pa láṣẹ fún ọ.

22 Ìró ogun wà ní ilẹ̀ náà,

Àjálù ńlá.

23 Ẹ wo bí wọ́n ṣe ṣẹ́ òòlù irin* gbogbo ayé, tí wọ́n sì fọ́ ọ!+

Ẹ wo bí Bábílónì ṣe di ohun àríbẹ̀rù láàárín àwọn orílẹ̀-èdè!+

24 Mo ti dẹkùn fún ọ, ó sì ti mú ọ, ìwọ Bábílónì,

Ìwọ kò sì mọ̀.

Wọ́n rí ọ, wọ́n sì gbá ọ mú,+

Torí pé Jèhófà ni o ta kò.

25 Jèhófà ti ṣí ilé ìṣúra rẹ̀,

Ó sì ń mú àwọn ohun ìjà ìbínú rẹ̀ jáde.+

Nítorí Olúwa Ọba Aláṣẹ, Jèhófà Ọlọ́run àwọn ọmọ ogun, ní iṣẹ́ kan

Ní ilẹ̀ àwọn ará Kálídíà.

26 Ẹ wá gbéjà kò ó láti àwọn ibi tó jìnnà.+

Ẹ ṣí àwọn àká rẹ̀.+

Ẹ kó o jọ bí òkìtì ọkà.

Ẹ pa á rẹ́.*+

Kó má sì ní ẹnikẹ́ni tó máa ṣẹ́ kù.

27 Pa gbogbo akọ ọmọ màlúù rẹ̀ ní ìpakúpa;+

Kí wọ́n sọ̀ kalẹ̀ lọ sí ibi tí wọ́n ti máa pa wọ́n.

Wọ́n gbé, nítorí ọjọ́ wọn ti dé,

Àkókò ìyà wọn!

28 Ìró àwọn tó ń sá lọ ń dún,

Àwọn tó ń sá àsálà láti ilẹ̀ Bábílónì,

Láti kéde ẹ̀san Jèhófà Ọlọ́run wa ní Síónì,

Ẹ̀san nítorí tẹ́ńpìlì rẹ̀.+

29 “Ẹ kó àwọn tafàtafà jọ láti gbéjà ko Bábílónì,

Gbogbo àwọn tó ń tẹ* ọrun.+

Ẹ pàgọ́ yí i ká; kí ẹnikẹ́ni má ṣe sá àsálà.

Ẹ san án fún un gẹ́gẹ́ bí iṣẹ́ ọwọ́ rẹ̀.+

Bí ó ti ṣe sí àwọn èèyàn ni kí ẹ ṣe sí i gẹ́lẹ́.+

Nítorí pé ó ti gbéra ga sí Jèhófà,

Sí Ẹni Mímọ́ Ísírẹ́lì.+

30 Torí náà, àwọn ọ̀dọ́kùnrin rẹ̀ á ṣubú ní àwọn gbàgede rẹ̀,+

Gbogbo àwọn ọmọ ogun rẹ̀ á sì ṣègbé* ní ọjọ́ yẹn,” ni Jèhófà wí.

31 “Wò ó! Mo dojú ìjà kọ ọ́,+ ìwọ aláìgbọràn,”+ ni Olúwa Ọba Aláṣẹ, Jèhófà Ọlọ́run àwọn ọmọ ogun wí,

“Nítorí ọjọ́ rẹ gbọ́dọ̀ dé, ní àkókò tí màá pè ọ́ wá jíhìn.

32 Ìwọ aláìgbọràn, wàá kọsẹ̀, wàá sì ṣubú,

Kò sì sí ẹni tó máa gbé ọ dìde.+

Màá sọ iná sí àwọn ìlú rẹ,

Á sì jó gbogbo ohun tó yí ọ ká run.”

33 Ohun tí Jèhófà Ọlọ́run àwọn ọmọ ogun sọ nìyí:

“Àwọn èèyàn Ísírẹ́lì àti Júdà ni à ń ni lára,

Gbogbo àwọn tó sì mú wọn lẹ́rú kò fi wọ́n sílẹ̀.+

Wọn ò jẹ́ kí wọ́n lọ.+

34 Àmọ́, Olùtúnrà wọn lágbára.+

Jèhófà Ọlọ́run àwọn ọmọ ogun ni orúkọ rẹ̀.+

Ó dájú pé á gba ẹjọ́ wọn rò,+

Kí ó lè fún ilẹ̀ náà ní ìsinmi+

Kí ó sì mú rúkèrúdò bá àwọn tó ń gbé ní Bábílónì.”+

35 “Idà kan wà tó dojú kọ àwọn ará Kálídíà,” ni Jèhófà wí,

“Ó dojú kọ àwọn tó ń gbé ní Bábílónì, ó sì dojú kọ àwọn ìjòyè rẹ̀ àti àwọn ọlọ́gbọ́n rẹ̀.+

36 Idà kan wà tó dojú kọ àwọn tó ń sọ ọ̀rọ̀ asán,* wọ́n á sì hùwà òmùgọ̀.

Idà kan wà tó dojú kọ àwọn jagunjagun rẹ̀, jìnnìjìnnì á sì bò wọ́n.+

37 Idà kan wà tó dojú kọ àwọn ẹṣin wọn àti àwọn kẹ̀kẹ́ ogun wọn,

Tó sì dojú kọ onírúurú àjèjì tó wà láàárín rẹ̀,

Wọ́n á dà bí obìnrin.+

Idà kan wà tó dojú kọ àwọn ìṣúra rẹ̀, ṣe ni wọ́n á kó wọn lọ.+

38 Ìparun máa wà yí ká omi rẹ̀, a ó mú kó gbẹ táútáú.+

Nítorí ilẹ̀ ère gbígbẹ́ ni,+

Wọ́n sì ń ṣe bíi wèrè nítorí àwọn ìran tó ń bani lẹ́rù tí wọ́n ń rí.

39 Nítorí náà, àwọn ẹranko tó ń gbé ní aṣálẹ̀ á máa gbé pẹ̀lú àwọn ẹranko tó ń hu,

Inú rẹ̀ sì ni ògòǹgò á máa gbé.+

Ẹnikẹ́ni ò sì ní gbé ibẹ̀ mọ́ láé,

Bẹ́ẹ̀ ni kò ní jẹ́ ibi tí àwọn èèyàn á máa gbé láti ìran dé ìran.”+

40 “Bí Ọlọ́run ṣe pa Sódómù àti Gòmórà+ àti àwọn ìlú tó yí wọn ká run,”+ ni Jèhófà wí, “kò ní sí ẹnì kankan tí á máa gbé ibẹ̀, kò sì ní sí èèyàn kankan tó máa tẹ̀ dó síbẹ̀.+

41 Wò ó! Àwọn èèyàn kan ń wọlé bọ̀ láti àríwá;

Orílẹ̀-èdè ńlá àti àwọn atóbilọ́lá ọba+ ni a ó gbé dìde

Láti àwọn ibi tó jìnnà jù lọ láyé.+

42 Wọ́n ń lo ọrun àti ọ̀kọ̀.*+

Ìkà ni wọ́n, wọn ò sì lójú àánú.+

Ìró wọn dà bíi ti òkun,+

Bí wọ́n ṣe ń gun ẹṣin wọn.

Bí ọkùnrin kan ṣoṣo ni wọ́n tò lọ́wọ̀ọ̀wọ́ láti gbógun tì ọ́, ìwọ ọmọbìnrin Bábílónì.+

43 Ọba Bábílónì ti gbọ́ ìròyìn nípa wọn,+

Ọwọ́ rẹ̀ sì rọ.+

Ìdààmú ti bá a,

Ìrora bíi ti obìnrin tó ń rọbí.

44 “Wò ó! Ẹnì kan máa wá gbéjà ko àwọn ibi ìjẹko Bábílónì tó wà ní ààbò bíi kìnnìún tó jáde látinú igbó kìjikìji lẹ́gbẹ̀ẹ́ Jọ́dánì, ṣùgbọ́n ní ìṣẹ́jú kan, màá mú kí wọ́n sá kúrò lọ́dọ̀ rẹ̀. Màá sì yan àyànfẹ́ lé e lórí.+ Nítorí ta ló dà bí èmi, ta ló lè sọ pé kí ni mò ń ṣe? Olùṣọ́ àgùntàn wo ló sì lè dúró níwájú mi?+ 45 Nítorí náà, ẹ gbọ́ ìpinnu* tí Jèhófà ṣe lórí Bábílónì + àti ohun tí ó ti rò nípa àwọn tó ń gbé ní Kálídíà.

Ó dájú pé, a ó wọ́ àwọn ẹran kéékèèké inú agbo ẹran lọ.

Ó máa sọ ibùgbé wọn di ahoro nítorí wọn.+

46 Nígbà tí wọ́n bá gba Bábílónì, ìró rẹ̀ á mú kí ilẹ̀ mì tìtì,

A ó sì gbọ́ igbe ẹkún láàárín àwọn orílẹ̀-èdè.”+

Yorùbá Publications (1987-2025)
Jáde
Wọlé
  • Yorùbá
  • Fi Ráńṣẹ́
  • Èyí tí mo fẹ́ràn jù
  • Copyright © 2025 Watch Tower Bible and Tract Society of Pennsylvania
  • Àdéhùn Nípa Lílò
  • Òfin
  • Ètò Nípa Ìsọfúnni Rẹ
  • JW.ORG
  • Wọlé
Fi Ráńṣẹ́