ÀKÁ ÌWÉ ORÍ ÍNTÁNẸ́Ẹ̀TÌ ti Watchtower
ÀKÁ ÌWÉ ORÍ ÍŃTÁNẸ́Ẹ̀TÌ
ti Watchtower
Yorùbá
ọ́
  • ẹ
  • ọ
  • ṣ
  • ń
  • ẹ́
  • ẹ̀
  • ọ́
  • ọ̀
  • BÍBÉLÌ
  • ÌTẸ̀JÁDE
  • ÌPÀDÉ
  • Sáàmù 106
  • Bíbélì Mímọ́ ti Ìtumọ̀ Ayé Tuntun

Kò sí fídíò kankan ní apá yìí.

Má bínú, fídíò yìí kò jáde.

Ohun Tó Wà Nínú Ìwé Sáàmù

      • Ísírẹ́lì kò moore

        • Kò pẹ́ tí wọ́n fi gbàgbé àwọn iṣẹ́ Ọlọ́run (13)

        • Wọ́n gbé ògo tó yẹ Ọlọ́run fún ère akọ màlúù (19, 20)

        • Wọn ò nígbàgbọ́ nínú ìlérí Ọlọ́run (24)

        • Wọ́n dara pọ̀ mọ́ àwọn tó ń sin Báálì (28)

        • Wọ́n fi àwọn ọmọ wọn rúbọ sí àwọn ẹ̀mí èṣù (37)

Sáàmù 106:1

Àlàyé ìsàlẹ́ ìwé

  • *

    Tàbí “Halelúyà!” “Jáà” ni ìkékúrú Jèhófà.

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +Lk 18:19
  • +1Kr 16:34; Ẹsr 3:11; Sm 103:17; 107:1

Atọ́ka

  • Ìwé Ìwádìí

    Ìwé Ọdọọdún—2015, ojú ìwé 2-3

Sáàmù 106:2

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +Sm 40:5

Sáàmù 106:3

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +Sm 15:1, 2; Ais 64:5

Sáàmù 106:4

Àlàyé ìsàlẹ́ ìwé

  • *

    Tàbí “ṣoore fún.”

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +Ne 5:19; Sm 51:18; 119:132

Sáàmù 106:5

Àlàyé ìsàlẹ́ ìwé

  • *

    Tàbí “máa fi ọ́ yangàn.”

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +Ẹk 19:5

Sáàmù 106:6

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +Ne 9:16; Sm 78:8
  • +Ẹsr 9:6; Da 9:5

Sáàmù 106:7

Àlàyé ìsàlẹ́ ìwé

  • *

    Tàbí “lóye ìtúmọ̀.”

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +Ẹk 14:11, 12

Atọ́ka

  • Ìwé Ìwádìí

    Ilé-Ìṣọ́nà,

    9/1/1995, ojú ìwé 19-20

Sáàmù 106:8

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +Sm 143:11; Isk 20:14
  • +Ẹk 9:16; Ro 9:17

Sáàmù 106:9

Àlàyé ìsàlẹ́ ìwé

  • *

    Tàbí “aginjù.”

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +Ẹk 14:21, 22

Sáàmù 106:10

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +Ẹk 14:30
  • +Ais 49:26

Sáàmù 106:11

Àlàyé ìsàlẹ́ ìwé

  • *

    Tàbí “tó ṣẹ́ kù.”

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +Ẹk 14:13, 28

Sáàmù 106:12

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +Ẹk 14:31
  • +Ẹk 15:1

Sáàmù 106:13

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +Ẹk 15:24; 16:2, 3; 17:7

Sáàmù 106:14

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +Nọ 11:4; Di 9:22; 1Kọ 10:6
  • +Ẹk 17:2; Sm 78:18; 1Kọ 10:9; Heb 3:8, 9

Sáàmù 106:15

Àlàyé ìsàlẹ́ ìwé

  • *

    Tàbí “ọkàn wọn.”

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +Nọ 11:31, 33; Sm 78:29-31

Sáàmù 106:16

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +Nọ 16:3
  • +Le 21:8; Nọ 16:5-7

Sáàmù 106:17

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +Nọ 16:27, 32

Sáàmù 106:18

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +Nọ 16:35

Sáàmù 106:19

Àlàyé ìsàlẹ́ ìwé

  • *

    Tàbí “ère dídà.”

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +Ẹk 32:4; Di 9:12

Sáàmù 106:20

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +Ẹk 20:4

Sáàmù 106:21

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +Di 32:18
  • +Di 4:34

Sáàmù 106:22

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +Sm 78:51
  • +Ẹk 14:25

Sáàmù 106:23

Àlàyé ìsàlẹ́ ìwé

  • *

    Ní Héb., “dúró sí àlàfo níwájú rẹ̀.”

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +Ẹk 32:10, 11; Di 9:14, 19

Sáàmù 106:24

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +Nọ 13:32; Di 8:7-9
  • +Nọ 14:11

Sáàmù 106:25

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +Nọ 14:2; Di 1:27
  • +Nọ 14:22, 23

Sáàmù 106:26

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +Nọ 14:28, 29; Heb 3:11

Sáàmù 106:27

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +Le 26:33; Di 4:27

Sáàmù 106:28

Àlàyé ìsàlẹ́ ìwé

  • *

    Tàbí “so ara wọn mọ́.”

  • *

    Ìyẹn, ẹbọ tí wọ́n rú sí òkú èèyàn tàbí sí àwọn ọlọ́run tí kò lẹ́mìí.

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +Nọ 25:3; Ho 9:10

Sáàmù 106:29

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +Nọ 25:6; Di 32:16
  • +Nọ 25:9; 1Kọ 10:8

Sáàmù 106:30

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +Nọ 25:7, 8

Sáàmù 106:31

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +Nọ 25:11-13

Sáàmù 106:32

Àlàyé ìsàlẹ́ ìwé

  • *

    Ó túmọ̀ sí “Ìjà.”

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +Nọ 20:2, 12; 27:13, 14

Atọ́ka

  • Ìwé Ìwádìí

    Ilé Ìṣọ́ (Ẹ̀dà Tó Wà fún Ìkẹ́kọ̀ọ́),

    7/2018, ojú ìwé 15

Sáàmù 106:33

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +Nọ 20:10

Atọ́ka

  • Ìwé Ìwádìí

    Ilé Ìṣọ́ (Ẹ̀dà Tó Wà fún Ìkẹ́kọ̀ọ́),

    7/2018, ojú ìwé 15

Sáàmù 106:34

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +Joṣ 16:10; 17:12; Ond 1:21
  • +Nọ 33:52; Di 7:1, 2

Sáàmù 106:35

Àlàyé ìsàlẹ́ ìwé

  • *

    Tàbí “Wọ́n sì kọ́ ìṣe wọn.”

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +Joṣ 15:63; Ond 1:33
  • +Ais 2:6

Atọ́ka

  • Ìwé Ìwádìí

    Gbádùn Ayé Rẹ Títí Láé!, ẹ̀kọ́ 14

Sáàmù 106:36

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +Ond 2:11, 12; 2Ọb 17:12
  • +Ẹk 23:32, 33

Atọ́ka

  • Ìwé Ìwádìí

    Gbádùn Ayé Rẹ Títí Láé!, ẹ̀kọ́ 14

Sáàmù 106:37

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +Di 12:31; 2Ọb 16:1, 3; 17:17, 18; Jer 7:30, 31; 1Kọ 10:20

Sáàmù 106:38

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +2Ọb 21:16
  • +Isk 16:20

Sáàmù 106:39

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +Jer 3:9

Sáàmù 106:41

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +Di 32:30; Ond 3:8
  • +Ond 10:6-8

Sáàmù 106:42

Àlàyé ìsàlẹ́ ìwé

  • *

    Ní Héb., “Wọ́n sì wà lábẹ́ ọwọ́ wọn.”

Sáàmù 106:43

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +Ond 10:11, 12; 1Sa 12:11
  • +Ond 4:1
  • +Ond 6:1-5

Sáàmù 106:44

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +Ond 2:18
  • +Ond 3:9

Sáàmù 106:45

Àlàyé ìsàlẹ́ ìwé

  • *

    Tàbí “Á kẹ́dùn.”

  • *

    Tàbí “ìfẹ́ rẹ̀ tí kì í yẹ̀ tó pọ̀ gidigidi.”

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +Ẹk 34:6; Di 32:36; Ais 63:7; Ida 3:32; Joẹ 2:13

Sáàmù 106:46

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +Ẹsr 9:9

Sáàmù 106:47

Àlàyé ìsàlẹ́ ìwé

  • *

    Tàbí “yọ̀ nínú ìyìn rẹ.”

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +Sm 79:9
  • +Jer 32:37
  • +1Kr 16:35

Sáàmù 106:48

Àlàyé ìsàlẹ́ ìwé

  • *

    Tàbí “Láti ayérayé dé ayérayé.”

  • *

    Tàbí “Kó rí bẹ́ẹ̀!”

  • *

    Tàbí “Halelúyà!” “Jáà” ni ìkékúrú Jèhófà.

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +1Kr 29:10; Sm 41:13; Lk 1:68

Àwọn míì

Sm 106:1Lk 18:19
Sm 106:11Kr 16:34; Ẹsr 3:11; Sm 103:17; 107:1
Sm 106:2Sm 40:5
Sm 106:3Sm 15:1, 2; Ais 64:5
Sm 106:4Ne 5:19; Sm 51:18; 119:132
Sm 106:5Ẹk 19:5
Sm 106:6Ne 9:16; Sm 78:8
Sm 106:6Ẹsr 9:6; Da 9:5
Sm 106:7Ẹk 14:11, 12
Sm 106:8Sm 143:11; Isk 20:14
Sm 106:8Ẹk 9:16; Ro 9:17
Sm 106:9Ẹk 14:21, 22
Sm 106:10Ẹk 14:30
Sm 106:10Ais 49:26
Sm 106:11Ẹk 14:13, 28
Sm 106:12Ẹk 14:31
Sm 106:12Ẹk 15:1
Sm 106:13Ẹk 15:24; 16:2, 3; 17:7
Sm 106:14Nọ 11:4; Di 9:22; 1Kọ 10:6
Sm 106:14Ẹk 17:2; Sm 78:18; 1Kọ 10:9; Heb 3:8, 9
Sm 106:15Nọ 11:31, 33; Sm 78:29-31
Sm 106:16Nọ 16:3
Sm 106:16Le 21:8; Nọ 16:5-7
Sm 106:17Nọ 16:27, 32
Sm 106:18Nọ 16:35
Sm 106:19Ẹk 32:4; Di 9:12
Sm 106:20Ẹk 20:4
Sm 106:21Di 32:18
Sm 106:21Di 4:34
Sm 106:22Sm 78:51
Sm 106:22Ẹk 14:25
Sm 106:23Ẹk 32:10, 11; Di 9:14, 19
Sm 106:24Nọ 13:32; Di 8:7-9
Sm 106:24Nọ 14:11
Sm 106:25Nọ 14:2; Di 1:27
Sm 106:25Nọ 14:22, 23
Sm 106:26Nọ 14:28, 29; Heb 3:11
Sm 106:27Le 26:33; Di 4:27
Sm 106:28Nọ 25:3; Ho 9:10
Sm 106:29Nọ 25:6; Di 32:16
Sm 106:29Nọ 25:9; 1Kọ 10:8
Sm 106:30Nọ 25:7, 8
Sm 106:31Nọ 25:11-13
Sm 106:32Nọ 20:2, 12; 27:13, 14
Sm 106:33Nọ 20:10
Sm 106:34Joṣ 16:10; 17:12; Ond 1:21
Sm 106:34Nọ 33:52; Di 7:1, 2
Sm 106:35Joṣ 15:63; Ond 1:33
Sm 106:35Ais 2:6
Sm 106:36Ond 2:11, 12; 2Ọb 17:12
Sm 106:36Ẹk 23:32, 33
Sm 106:37Di 12:31; 2Ọb 16:1, 3; 17:17, 18; Jer 7:30, 31; 1Kọ 10:20
Sm 106:382Ọb 21:16
Sm 106:38Isk 16:20
Sm 106:39Jer 3:9
Sm 106:41Di 32:30; Ond 3:8
Sm 106:41Ond 10:6-8
Sm 106:43Ond 10:11, 12; 1Sa 12:11
Sm 106:43Ond 4:1
Sm 106:43Ond 6:1-5
Sm 106:44Ond 2:18
Sm 106:44Ond 3:9
Sm 106:45Ẹk 34:6; Di 32:36; Ais 63:7; Ida 3:32; Joẹ 2:13
Sm 106:46Ẹsr 9:9
Sm 106:47Sm 79:9
Sm 106:47Jer 32:37
Sm 106:471Kr 16:35
Sm 106:481Kr 29:10; Sm 41:13; Lk 1:68
  • Bíbélì Mímọ́ ti Ìtumọ̀ Ayé Tuntun
  • 1
  • 2
  • 3
  • 4
  • 5
  • 6
  • 7
  • 8
  • 9
  • 10
  • 11
  • 12
  • 13
  • 14
  • 15
  • 16
  • 17
  • 18
  • 19
  • 20
  • 21
  • 22
  • 23
  • 24
  • 25
  • 26
  • 27
  • 28
  • 29
  • 30
  • 31
  • 32
  • 33
  • 34
  • 35
  • 36
  • 37
  • 38
  • 39
  • 40
  • 41
  • 42
  • 43
  • 44
  • 45
  • 46
  • 47
  • 48
Bíbélì Mímọ́ ti Ìtumọ̀ Ayé Tuntun
Sáàmù 106:1-48

Sáàmù

106 Ẹ yin Jáà!*

Ẹ fi ọpẹ́ fún Jèhófà, nítorí ó jẹ́ ẹni rere;+

Ìfẹ́ rẹ̀ tí kì í yẹ̀ wà títí láé.+

 2 Ta ló lè kéde gbogbo iṣẹ́ ńlá tí Jèhófà ṣe

Tàbí tó lè kéde gbogbo iṣẹ́ rẹ̀ tó yẹ fún ìyìn?+

 3 Aláyọ̀ ni àwọn tó ń ṣe ohun tó bá ẹ̀tọ́ mu,

Àwọn tó ń ṣe ohun tí ó tọ́ nígbà gbogbo.+

 4 Jèhófà, rántí mi nígbà tí o bá ń ṣojú rere sí* àwọn èèyàn rẹ.+

Fi àwọn iṣẹ́ ìgbàlà rẹ tọ́jú mi,

 5 Kí n lè gbádùn oore tí ò ń ṣe fún àwọn àyànfẹ́ rẹ,+

Kí n lè máa bá orílẹ̀-èdè rẹ yọ̀,

Kí n lè máa ṣògo bí mo ṣe ń yìn ọ́* pẹ̀lú ogún rẹ.

 6 A ti dẹ́ṣẹ̀ bí àwọn baba ńlá wa;+

A ti ṣe ohun tí kò dáa; a ti hùwà burúkú.+

 7 Àwọn baba ńlá wa ní Íjíbítì kò mọyì* àwọn iṣẹ́ àgbàyanu rẹ.

Wọn ò rántí ìfẹ́ rẹ tí kì í yẹ̀ tó pọ̀ gidigidi,

Wọ́n ṣọ̀tẹ̀ ní òkun, létí Òkun Pupa.+

 8 Àmọ́, ó gbà wọ́n sílẹ̀ nítorí orúkọ rẹ̀,+

Kí wọ́n lè mọ bí agbára rẹ̀ ṣe pọ̀ tó.+

 9 Ó bá Òkun Pupa wí, ó sì gbẹ;

Ó mú wọn gba ìsàlẹ̀ rẹ̀ bí ẹni gba aṣálẹ̀* kọjá;+

10 Ó gbà wọ́n lọ́wọ́ elénìní,+

Ó sì gbà wọ́n pa dà lọ́wọ́ ọ̀tá.+

11 Omi bo àwọn elénìní wọn;

Kò sí ìkankan lára wọn tó yè bọ́.*+

12 Nígbà náà, wọ́n ní ìgbàgbọ́ nínú ìlérí rẹ̀;+

Wọ́n bẹ̀rẹ̀ sí í kọrin yìn ín.+

13 Àmọ́ kò pẹ́ tí wọ́n fi gbàgbé ohun tó ṣe;+

Wọn ò dúró de ìmọ̀ràn rẹ̀.

14 Wọ́n jẹ́ kí ìfẹ́kúfẹ̀ẹ́ gbà wọ́n lọ́kàn ní aginjù;+

Wọ́n dán Ọlọ́run wò ní aṣálẹ̀.+

15 Ó fún wọn ní ohun tí wọ́n béèrè,

Àmọ́ lẹ́yìn náà, ó fi àrùn kọ lù wọ́n, wọ́n* sì rù hangogo.+

16 Ní ibùdó, wọ́n jowú Mósè

Àti Áárónì,+ ẹni mímọ́ Jèhófà.+

17 Ni ilẹ̀ bá lanu, ó gbé Dátánì mì,

Ó sì bo àwọn tó kóra jọ sọ́dọ̀ Ábírámù.+

18 Iná sọ láàárín àwùjọ wọn;

Ọwọ́ iná jó àwọn ẹni burúkú run.+

19 Wọ́n ṣe ère ọmọ màlúù kan ní Hórébù,

Wọ́n sì forí balẹ̀ fún ère onírin;*+

20 Wọ́n gbé ògo mi

Fún ère akọ màlúù tó ń jẹ koríko.+

21 Wọ́n gbàgbé Ọlọ́run,+ Olùgbàlà wọn,

Ẹni tó ṣe àwọn ohun ńlá ní Íjíbítì,+

22 Àwọn iṣẹ́ àgbàyanu ní ilẹ̀ Hámù,+

Àwọn ohun tó ń bani lẹ́rù ní Òkun Pupa.+

23 Díẹ̀ ló kù kó sọ pé kí wọ́n pa wọ́n rẹ́,

Àmọ́ Mósè àyànfẹ́ rẹ̀ bá wọn bẹ̀bẹ̀*

Láti yí ìbínú rẹ̀ tó ń pani run pa dà.+

24 Síbẹ̀, wọn ò ka ilẹ̀ dáradára náà sí;+

Wọn ò nígbàgbọ́ nínú ìlérí rẹ̀.+

25 Ṣe ni wọ́n ń ráhùn nínú àgọ́ wọn;+

Wọn ò fetí sí ohùn Jèhófà.+

26 Torí náà, ó gbé ọwọ́ rẹ̀ sókè láti búra nípa wọn

Pé òun máa mú kí wọ́n ṣubú ní aginjù;+

27 Pé òun máa mú kí àtọmọdọ́mọ wọn ṣubú láàárín àwọn orílẹ̀-èdè

Àti pé òun máa tú wọn ká sí àwọn ilẹ̀ náà.+

28 Lẹ́yìn náà, wọ́n dara pọ̀ mọ́ àwọn tó ń sin* Báálì Péórì,+

Wọ́n sì ń jẹ ẹbọ tí wọ́n rú sí òkú.*

29 Wọ́n fi àwọn ohun tí wọ́n ń ṣe mú Un bínú,+

Àjàkálẹ̀ àrùn sì bẹ́ sílẹ̀ láàárín wọn.+

30 Àmọ́ nígbà tí Fíníhásì dìde, tí ó sì dá sí i,

Àjàkálẹ̀ àrùn náà dáwọ́ dúró.+

31 A sì kà á sí òdodo fún un

Láti ìran dé ìran àti títí láé.+

32 Wọ́n múnú bí I níbi omi Mẹ́ríbà,*

Wọ́n sì fi tiwọn kó bá Mósè.+

33 Wọ́n gbé ẹ̀mí rẹ̀ gbóná,

Ó sì fi ẹnu rẹ̀ sọ̀rọ̀ láìronú.+

34 Wọn ò pa àwọn èèyàn náà run,+

Bí Jèhófà ṣe pàṣẹ fún wọn.+

35 Àmọ́ wọ́n ń bá àwọn orílẹ̀-èdè náà ṣe wọlé wọ̀de,+

Wọ́n sì ń hùwà bíi tiwọn.*+

36 Wọ́n ń sin àwọn òrìṣà wọn,+

Àwọn òrìṣà náà sì di ìdẹkùn fún wọn.+

37 Wọ́n ń fi àwọn ọmọkùnrin wọn

Àti àwọn ọmọbìnrin wọn rúbọ sí àwọn ẹ̀mí èṣù.+

38 Wọ́n ń ta ẹ̀jẹ̀ aláìṣẹ̀ sílẹ̀,+

Ẹ̀jẹ̀ àwọn ọmọkùnrin wọn àti ti àwọn ọmọbìnrin wọn

Tí wọ́n fi rúbọ sí àwọn òrìṣà Kénáánì;+

Ilẹ̀ náà sì di ẹlẹ́gbin nítorí ìtàjẹ̀sílẹ̀.

39 Àwọn iṣẹ́ wọn sọ wọ́n di aláìmọ́,

Wọ́n sì ṣe àgbèrè ẹ̀sìn.+

40 Torí náà, ìbínú Jèhófà ru sí àwọn èèyàn rẹ̀,

Ó sì bẹ̀rẹ̀ sí í kórìíra ogún rẹ̀.

41 Léraléra ló fi wọ́n lé àwọn orílẹ̀-èdè lọ́wọ́,+

Kí àwọn tó kórìíra wọn lè ṣàkóso lé wọn lórí.+

42 Àwọn ọ̀tá wọn ni wọ́n lára,

Wọ́n sì jẹ gàba lé wọn lórí.*

43 Ọ̀pọ̀ ìgbà ló gbà wọ́n sílẹ̀,+

Àmọ́ wọ́n á ṣọ̀tẹ̀, wọ́n á sì ṣàìgbọràn,+

A ó sì rẹ̀ wọ́n sílẹ̀ nítorí àṣìṣe wọn.+

44 Àmọ́ á tún rí ìdààmú tó bá wọn,+

Á sì gbọ́ igbe ìrànlọ́wọ́ wọn.+

45 Nítorí wọn, á rántí májẹ̀mú rẹ̀,

Àánú á sì ṣe é* nítorí ìfẹ́ rẹ̀ tó ga tí kì í sì í yẹ̀.*+

46 Á jẹ́ kí àánú wọn máa ṣe

Gbogbo àwọn tó mú wọn lẹ́rú.+

47 Gbà wá, Jèhófà Ọlọ́run wa,+

Kí o sì kó wa jọ látinú àwọn orílẹ̀-èdè+

Ká lè máa fi ọpẹ́ fún orúkọ mímọ́ rẹ,

Ká sì máa yọ̀ bí a ṣe ń yìn ọ́.*+

48 Ìyìn ni fún Jèhófà Ọlọ́run Ísírẹ́lì

Títí láé àti láéláé.*+

Kí gbogbo èèyàn sì sọ pé, “Àmín!”*

Ẹ yin Jáà!*

Yorùbá Publications (1987-2025)
Jáde
Wọlé
  • Yorùbá
  • Fi Ráńṣẹ́
  • Èyí tí mo fẹ́ràn jù
  • Copyright © 2025 Watch Tower Bible and Tract Society of Pennsylvania
  • Àdéhùn Nípa Lílò
  • Òfin
  • Ètò Nípa Ìsọfúnni Rẹ
  • JW.ORG
  • Wọlé
Fi Ráńṣẹ́